< 1 Sa:miuele 21 >

1 Da: ibidi da Ahimelege (gobele salasu dunu) Noube moilai bai bagadega esalu, amoga asi. Ahimelege da hisu yaguguli ema gousa: musa: misini, amane adole ba: i, “Di da abuliba: le disuwane goeguda: misibala: ?”
Dafidi sì wá sí Nobu sọ́dọ̀ Ahimeleki àlùfáà, Ahimeleki sì bẹ̀rù láti pàdé Dafidi, ó sì wí fún un pé, “Èéha ti rí tí o fi ṣe ìwọ nìkan, àti tí kò sì sí ọkùnrin kan tí ó pẹ̀lú rẹ?”
2 Da: ibidi da bu adole i, “Na da hina bagade ea hamobegawane goeguda: misi. E da na hamoma: ne asunasi we enoma mae sia: ma: ne sia: i. Be na dunu oda ni ilegei sogea nama doaga: ma: ne adosi.
Dafidi sì wí fún Ahimeleki àlùfáà pé, “Ọba pàṣẹ iṣẹ́ kan fún mi, ó sì wí fún mi pé, ‘Má ṣe jẹ́ kí ẹnìkan mọ ìdí iṣẹ́ náà ti mo rán ọ, àti èyí tí èmi ti pàṣẹ fún ọ.’ Èmi sì yan àwọn ìránṣẹ́ mi sí ibí báyìí.
3 Di da adi ha: i manu ganabela: ? Di da nama agi gobei biyale galea o eno liligi gagui galea, nama ima.”
Ǹjẹ́ kín ni ó wà ní ọwọ́ rẹ̀? Fún mi ni ìṣù àkàrà márùn-ún tàbí ohunkóhun tí o bá rí.”
4 Ahimelege da amane sia: i, “Na da agi ga: gi gobei udigili dialebe hame. Be Godema gobele salimusa: sema liligi fawane gala. Dia dunu da uda fisili, gilisili hame golai galea, defea digili moma.”
Àlùfáà náà sí dá Dafidi lóhùn ó sì wí pé, “Kò sí àkàrà mìíràn lọ́wọ́ mi bí kò ṣe àkàrà mímọ́. Kìkì pé bi àwọn ọmọkùnrin bá ti pa ara wọn mọ́ kúrò lọ́dọ̀ obìnrin!”
5 Da: ibidi da bu adole i, “Defea! Na dunu da uda fisili, gilisili hame golai. Ninia da eso huluane hina bagade ea hawa: hamoma: ne ahoasea, sema defele udama hame doaga: sa. Wali hamobe da bagadeba: le, ninia da ledo mae hamoma: ne, amo sema baligili dawa: sa.”
Dafidi sì dá àlùfáà náà lóhùn, ó sì wí fún un pé, “Nítòótọ́ ni a tí ń pa ara wá mọ́ kúrò lọ́dọ̀ obìnrin láti ìwọ̀n ọjọ́ mẹ́ta wá, tí èmí ti jáde. Gbogbo nǹkan àwọn ọmọkùnrin náà ni ó mọ́, àti àkàrà náà sì wá dàbí àkàrà mìíràn, pàápàá nígbà tí ó jẹ́ pé òmíràn wà tí a yà sí mímọ́ lónìí nínú ohun èlò náà!”
6 Amaiba: le, gobele salasu dunu da sema agi ga: gi gobei amo Da: ibidima i. Bai sema agi gobei Godema ianu, (amo da gaheabolo agi gobei legema: ne, musa: agi ga: gi da sema fafai amoga fadegai ba: i) amo fawane dialebe ba: i.
Bẹ́ẹ̀ ni àlùfáà náà sì fi àkàrà mímọ́ fún un; nítorí tí kò sí àkàrà mìíràn níbẹ̀ bí kò ṣe àkàrà ìfihàn tí a ti kó kúrò níwájú Olúwa, láti fi àkàrà gbígbóná síbẹ̀ ní ọjọ́ tí a kó o kúrò.
7 (Solo ea laigebo fofoi bisilua ouligisu dunu, Idome soge dunu ea dio amo Douege, da amo esoha amogawi esalu. Bai e da Gode Ea sema hawa: hamosu hamoma: ne misi.)
Ọkùnrin kan nínú àwọn ìránṣẹ́ Saulu sì ń bẹ níbẹ̀ lọ́jọ́ náà, tí a tí dádúró síwájú Olúwa; orúkọ rẹ̀ sì ń jẹ́ Doegi, ará Edomu olórí nínú àwọn darandaran Saulu.
8 Da: ibidi da Ahimelegema amane sia: i, “Di da goge agei o gegesu gobihei sedade nama imunu ganoma: bela: ? Hina bagade da nama hedolowane masa: ne sia: beba: le, na da gegesu gobihei o gegesu liligi eno gagumu hamedei ba: i.”
Dafidi sì tún wí fún Ahimeleki pé, “Kò sí ọ̀kọ̀ tàbí idà lọ́wọ́ rẹ níhìn-ín? Nítorí tí èmi kò mú idà mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò mú nǹkan ìjà mi lọ́wọ́, nítorí pé iṣẹ́ ọba náà jẹ́ iṣẹ́ ìkánjú.”
9 Ahimelege da bu adole i, “Na da Filisidini dunu Goulaia: de (amo di da Ila fagoga fane legei) amo ea gegesu gobihei fawane gala. Amo da Ifode baligia abulaga lala: gili diala. Di hanai galea, lama. Gegesu liligi eno da hame. Afa gofawane!” Da: ibidi da amane sia: i, “Nama ima! Amo gobihei da noga: idafa. Baligisu liligi da hame gala.”
Àlùfáà náà sì wí pé, “Idà Goliati ará Filistini tí ó pa ní àfonífojì Ela ní ń bẹ, wò ó, a fi aṣọ kan wé e lẹ́yìn efodu; bí ìwọ yóò bá mú èyí, mú un; kò sì sí òmíràn níhìn-ín mọ́ bí kò ṣe ọ̀kan náà.” Dafidi sì wí pé, “Kò sí èyí tí ó dàbí rẹ̀ fún mi.”
10 Amaiba: le, Da: ibidi da asi. E da Soloba: le hobeale asili, Ga: de moilai bai bagade hina bagade A: igise ema doaga: i.
Dafidi sì dìde, o sì sá ni ọjọ́ náà níwájú Saulu, ó sì lọ sọ́dọ̀ Akiṣi, ọba Gati.
11 Hina bagade A: igise ea eagene ouligisu dunu da ema amane sia: i, “Amo dunu da Isala: ili soge hina bagade Da: ibidi. Amo dunu ea hou olelema: ne, uda da siogolala amane gesami hea: i, ‘Solo da 1,000 baligili gale fane legei, be Da: ibidi da 10,000 baligili gale fanelegei.”
Àwọn ìránṣẹ́ Akiṣi sì wí fún un pé, “Èyí ha kọ́ ní Dafidi ọba ilẹ̀ náà? Ǹjẹ́ wọn kò ha ti dárin ti wọ́n sì gbe orin nítorí rẹ̀, tí wọ́n sì jó pé, “‘Saulu pa ẹgbẹ̀rún tirẹ̀. Dafidi sì pa ẹgbàárùn-ún tirẹ̀’?”
12 Da: ibidi da ilia amane sia: dabe nababeba: le, oso dogone beda: i. Amola e da hina bagade A: igiseba: le bagadewane beda: i.
Dafidi sì pa ọ̀rọ̀ wọ̀nyí í mọ́ ni ọkàn rẹ̀, ó sì bẹ̀rù Akiṣi ọba Gati gidigidi.
13 Amaiba: le, habogala dunu da e gadenena manebe ba: loba, e da ogogole doulasi elabusu dunu agoane hamosu, amola ilia da e gagulaligili ba: su, be e da bu gagaba: gisu. E da moilai logo ga: su damana udigili dedesu amola lafidi defo sasia: le, mayabo damana bodola: i.
Òun sì pa ìṣe rẹ̀ dà níwájú wọn, ó sì sọ ara rẹ̀ di aṣiwèrè ní ọwọ́ wọn, ó sì ń fi ọwọ́ rẹ̀ ha ìlẹ̀kùn ojú ọ̀nà, ó sì ń wá itọ́ sí irùngbọ̀n rẹ̀.
14 Amaiba: le, A:igise da ea eagene ouligisu dunu ilima amane sia: i, “Ba: ma! Amo dunu da doulasi dagoi. Dilia da abuliba: le e nama oule misibala: ?
Nígbà náà ni Akiṣi wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Wó o, nítorí kín ni ẹ̀yin ṣe mú un tọ̀ mí wá.
15 Na da doulasi dunu bagohame ouligisa. Abuliba: le eno agoaiwane nina: diasua guiguda: , nama ougima: ne oule mahabela: ?”
Mo ha ni un fi aṣiwèrè ṣe? Tí ẹ̀yin fi mú èyí tọ̀ mí wá láti hu ìwà aṣiwèrè níwájú mi? Eléyìí yóò ha wọ inú ilé mi?”

< 1 Sa:miuele 21 >