< 1 Sa:miuele 16 >

1 Hina Gode da Sa: miuelema amane sia: i, “Di da habowali seda Solo ea hou dawa: beba: le da: i dione fofaginanoma: bela: ? E da Isala: ili dunu ilima hina bagade bu mae esaloma: ne, Na da ea logo hedofai dagoi. Be wali di olife susuligi lale, Bedeleheme moilaiga dunu ea dio amo Yesi ea diasuga masa. Bai Na da egefe afae Isala: ili hina bagade hamoma: ne ilegei dagoi.
Olúwa sọ fún Samuẹli pé, “Yóò ha ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò máa dárò Saulu, nígbà tí ó jẹ́ pé mo ti kọ̀ ọ́ ní ọba lórí Israẹli? Rọ òróró kún inú ìwo rẹ, kí o sì mú ọ̀nà rẹ pọ̀n, Èmi rán ọ sí Jese ará Bẹtilẹhẹmu. Èmi ti yan ọ̀kan lára àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ láti jẹ ọba.”
2 Sa: miuele da amane sia: i, “Na da agoane habodane hamoma: bela: ? Solo da amo nabasea, ea da na fane legemu!” Hina Gode da bu adole i, “Di da bulamagau mano gaguli asili, amo Hina Godema gobele salimusa: misi sia: ma.
Ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Báwo ni èmi yóò ṣe lọ? Bí Saulu bá gbọ́ nípa rẹ̀, yóò pa mi.” Olúwa wí pé, “Mú abo ẹgbọrọ màlúù kan pẹ̀lú rẹ, kí o sì wí pé, ‘Èmi wá láti wá rú ẹbọ sí Olúwa.’
3 Amo gobele salabe amoga Yesi misa: ne sia: ne, amola Na da dima agoane hamoma: ya adomu. Di da dunu Na dima adomu, amo hina bagade hamoma: ne susuligi sogagala: le ilegema!”
Pe Jese wá sí ibi ìrúbọ náà, Èmi yóò sì fi ohun tí ìwọ yóò ṣe hàn ọ́. Ìwọ yóò fi òróró yàn fún mi, ẹni tí èmi bá fihàn ọ́.”
4 Sa: miuele da Hina Gode Ea adoi defele hamoi. E da Bedeleheme moilaiga asili, moilai ouligisu dunu da beda: ga yagugusa ema misini, amane adole ba: i, “Ba: la: lusu! Di da olofomusa: sofe misibala: ?”
Samuẹli ṣe ohun tí Olúwa sọ. Nígbà tí ó dé Bẹtilẹhẹmu, àyà gbogbo àgbàgbà ìlú já, nígbà tí wọ́n pàdé rẹ̀. Wọ́n béèrè pé, “Ṣé àlàáfíà ní ìwọ bá wá?”
5 “Ma!” e da adole i. “Na da Hina Godema gobele salimusa: misi. Dilia ledo dodofelalu, nini masunu.” Amola Yesi amola egefe ilia ledo dodofelalu, amo gobele salabe amoga misa: ne sia: i.
Samuẹli sì dáhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni àlàáfíà ni; mo wá láti wá rú ẹbọ sí Olúwa. Ẹ ya ara yín sí mímọ́, kí ẹ sì wá rú ẹbọ pẹ̀lú mi.” Nígbà náà ni ó sì ya Jese sí mímọ́ pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀, ó sì pè wọ́n wá sí ibi ìrúbọ náà.
6 Ilia da doaga: beba: le, Sa: miuele da Yesi egefe Ilaia: be ba: i. Hisu amane sia: i, “Amo dunu da Hina Gode ba: ma: ne lela. Dafawane ewane Hina Gode da ilegei dagoi.”
Nígbà tí wọ́n dé, Samuẹli rí Eliabu, ó rò nínú ara rẹ̀ pé lóòótọ́ ẹni òróró Olúwa dúró níbí níwájú Olúwa.
7 Be Hina Gode da ema amane sia: i, “E goi sedade amola ayeligi noga: i ba: sa amo mae dawa: ma. Na da amo dunu hame ilegei. Bai Na da dunu ilia asigi dawa: suga ilegebe agoane, hame ilegesa. Osobo bagade dunu da dabuagado hou, amo ba: lu ilegesa. Be Na da dunu ea dogo ganodini ba: lu, ilegesa.”
Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Samuẹli pé, “Má ṣe wo ti ìrísí rẹ̀ tàbí ti gíga rẹ̀, nítorí èmi ti kọ̀ ọ́ sílẹ̀. Olúwa kì í wo ohun tí ènìyàn máa ń wò. Ènìyàn máa ń wo òde ara ṣùgbọ́n Olúwa máa ń wo ọkàn.”
8 Amalalu, Yesi da egefe eno Abinada: be wele sia: ne, amo Sa: miuelema oule misi. Be Sa: miuele da amane sia: i, “Go hame! Hina Gode da goma hame ilegei.”
Nígbà náà ni Jese pe Abinadabu, ó sì jẹ́ kí ó rìn kọjá ní iwájú Samuẹli. Ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Olúwa kò yan ẹni yìí.”
9 Amalalu, Yesi da egefe eno amo Siama oule misi. Be Sa: miuele da amane sia: i, “Hame! Hina Gode da goma amolawane hame ilegei.”
Jese sì jẹ́ kí Ṣamma rìn kọjá ní iwájú Samuẹli, ṣùgbọ́n Samuẹli wí pé, “Olúwa kò yan ẹni yìí náà.”
10 Amanemusu hamonana, Yesi da egefe fesuale amo huluane Sa: miuelema oule misi. Amola Sa: miuele da ema amane sia: i, “Hina Gode da golalima afae hame ilegei.”
Jese jẹ́ kí àwọn ọmọ rẹ̀ méje rìn kọjá ní iwájú Samuẹli ṣùgbọ́n Samuẹli sọ fún un pé, “Olúwa kò yan àwọn wọ̀nyí.”
11 Amalalu, e da Yesima adole ba: i, “Di da mano eno ganabela: ?” Yesi da bu adole i, “Na da mano afae ufidafa gala. Be e da eno sogega sibi ouligilala.” Sa: miuele da amane sia: i, “E goeguda: misa: ne sia: ma. E da goeguda: doaga: sea fawane, ninia da Godema gobele salasu imunu.”
Nígbà náà ni ó béèrè lọ́wọ́ Jese pé, “Ṣé èyí ni gbogbo àwọn ọmọ rẹ?” Jese dáhùn pé, “Ó ku àbíkẹ́yìn wọn, ó ń tọ́jú agbo àgùntàn.” Samuẹli sì wí pé, “Rán ìránṣẹ́ lọ pè é wá; àwa kò ní jókòó títí òun yóò fi dé.”
12 Amaiba: le, Yesi da amo mano lala misa: ne sia: si. Amo goi da manebe ba: loba, e da goi ayeligi da: da: loi amola ela: menesi goi ba: i, amola ea si da nenemeginisi ba: i. Hina Gode da Sa: miuelema amane sia: i, “Goefa galu! Ema ilegelesima!”
Ó sì ránṣẹ́ sí i, wọ́n sì mú un wọlé wá, ó jẹ́ ẹni tó mọ́ra, àwọ̀ ara rẹ̀ dùn ún wò, ó jẹ́ arẹwà gidigidi. Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Dìde kí o sì fi òróró yàn án, òun ni ẹni náà.”
13 Sa: miuele da olife susuligi lale, Da: ibidi yolalali ilia midadi amo Da: ibidima unasi. Amo galuwane, Hina Gode Ea A: silibu da Da: ibidi ea da: iga aligila sa: ili, amola ela gilisi amo esoha amola amoinini amoga esalusu. Amalu, Sa: miuele da La: imaga buhagi.
Nígbà náà ni Samuẹli mú ìwo òróró, ó sì ta á sí i ní orí ní iwájú àwọn ẹ̀gbọ́n rẹ̀, láti ọjọ́ náà lọ, Ẹ̀mí Mímọ́ Olúwa wá sí orí Dafidi nínú agbára. Samuẹli sì lọ sí Rama.
14 Hina Gode Ea A: silibu Hadigidafa da Solo yolesili amola Hina Gode da wadela: i a: silibu Soloma asunasi. Amoga se nababeba: le, Solo da bagadewane gagaba: gilalu.
Nísinsin yìí, ẹ̀mí Olúwa ti kúrò lára Saulu, ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Olúwa sì ń yọ ọ́ lẹ́nu.
15 Solo ea hawa: hamosu dunu da ema amane sia: i, “Ninia dawa: , Hina Gode da wadela: i a: silibu dima asunasi, amola amoga di da se nabane gagaba: gilalu.
Àwọn ìránṣẹ́ Saulu sì wí fún un pé, “Wò ó, ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá ń yọ ọ́ lẹ́nu.
16 Amaiba: le, hina! Dia da ninima sia: sea, ninia da sani baidama dusu dawa: dunu hogomu. Amasea, wadela: i a: silibu da dima masea, amo dunu da sani baidama dunigala: mu, amasea di da bu noga: mu.”
Jẹ́ kí olúwa wa pàṣẹ fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ tí ó wà níhìn-ín láti wa ẹnìkan tí ó lè fi dùùrù kọrin. Yóò sì ṣe é nígbà tí ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run bá bà lé ọ, ìwọ yóò sì sàn.”
17 Solo da amane sia: i, “Defea! Dunu amo da sani baidama noga: le dubi hogole, nama oule misa.”
Nígbà náà ni Saulu wí fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Ẹ wá ẹnìkan tí ó lè kọrin dáradára kí ẹ sì mú u wá fún mi.”
18 Solo ea hawa: hamosu dunu afae da amane sia: i “Bedeleheme moilaiga Yesi egefe afae da sani baidama dusu bagade dawa: E da gasa bagade amola ayeligi dunu. E da dadi gagui dunu noga: i amola sia: sia: mu defele esala. Hina Gode da ela esala.”
Ọ̀kan nínú ìránṣẹ́ náà dáhùn pé, “Èmi ti ri ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Jese ti Bẹtilẹhẹmu tí ó mọ orin kọ, ó jẹ́ alágbára àti ológun. Ó ní ọgbọ́n ọ̀rọ̀ òun sì dára ní wíwò. Olúwa sì wà pẹ̀lú u rẹ̀.”
19 Amaiba: le, Solo da Yesima sia: agoane sia: na masa: ne dunu asunasi, “Yesi! Dia mano Da: ibidi amo sibi ouligilalebe, go nama misa: ne asunasima.”
Saulu sì rán oníṣẹ́ sí Jese wí pé, “Rán Dafidi ọmọ rẹ sí mi, ẹni tí ó ń ṣọ́ àgùntàn.”
20 Yesi da Da: ibidima goudi mano afae amola dougi afae (amo da: iya agi gobei lidili legele) amola waini hano bulamagau gadofo dabaga sali afae amo huluane iasisili, Soloma masa: ne, asunasi.
Jese sì mú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ti a di ẹrù lé àti ìgò ọtí wáìnì àti ọmọ ewúrẹ́; ó sì rán wọn nípa ọwọ́ Dafidi ọmọ rẹ̀ sí Saulu.
21 Da: ibidi da Soloma misini doaga: le, ea hawa: hamosu amo hamonanu. Solo da Da: ibidima bagadewane dogolegei. E da Da: ibidi amo ea gegesu liligi gaguli ahoasu dunu hamoma: ne ilegei.
Dafidi sì tọ Saulu lọ, ó sì dúró níwájú rẹ̀, òun sì fẹ́ ẹ gidigidi, Dafidi sì wá di ọ̀kan nínú àwọn tí ń ru ìhámọ́ra rẹ̀.
22 Amalalu, Solo da Yesima sia: amane sia: si, “Na da Da: ibidima dogolegei. E da na hawa: hamosu ganodini esaloma: ma.”
Nígbà náà ni Saulu ránṣẹ́ sí Jese pé, “Jẹ́ kí Dafidi dúró níwájú mi, nítorí tí ó wù mí.”
23 Amogainini, Gode Ea da wadela: i a: silibu amo Soloma asunasi, amo mabe ba: loba, Da: ibidi da ea sani baidama lale, dusu. Amalalu, wadela: i a: silibu da Solo yolesili, e da bu noga: le, amola defea hamosu.
Ó sì ṣe, nígbà tí ẹ̀mí búburú láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run wá bá dé sí Saulu, Dafidi a sì fi ọwọ́ rẹ̀ kọrin lára dùùrù: a sì san fún Saulu, ara rẹ̀ a sì dá; ẹ̀mí búburú náà a sì fi sílẹ̀.

< 1 Sa:miuele 16 >