< 1 Sa:miuele 11 >
1 Oubi afae baligili gomane, A:mone hina bagade Na: iha: sie da ea dadi gagui dunu bisili asili Gilia: de fi ganodini Ya: ibese moilai bai bagade fi ilima gegemusa: asi. Ya: ibese dunu da Na: iha: siema amane sia: i, “Dia ninima gousa: su hamoma. Amasea, dia da nini ouligima: mu.”
Nahaṣi ará Ammoni gòkè lọ, ó sì dó ti Jabesi Gileadi, gbogbo ọkùnrin Jabesi sì wí fún Nahaṣi pé, “Bá wa dá májẹ̀mú, àwa yóò sì máa sìn ọ́.”
2 Na: iha: sie da bu adole i, “Na da dilima gousa: su hamomu be hou afae fawane fa: no bobogemu. Na da dilia dunu huluane ilia lobodafadini si duga: le fasima: ne sia: sea fawane, na da dilima gousa: su hamomu. Amasea Isala: ili fi huluane da gogosiamu!”
Ṣùgbọ́n Nahaṣi ará Ammoni sì wí fún un pé, “Nípa èyí ni èmi yóò fi bá a yín ṣe ìpinnu, nípa yíyọ gbogbo ojú ọ̀tún yín kúrò, èmi yóò ṣì fi yín ṣe ẹlẹ́yà lójú gbogbo Israẹli.”
3 Ya: ibese ouligisu hina ilia da amane sia: i, “Ninima eso fesuale ima! Amo esoga ninia da Isala: ili fi ganodini amo sia: sisa: i lamu. Amasea, ninia da fidisu dunu hame ba: sea, dima dia sia: i defele gousa: su hamomu.”
Àwọn àgbàgbà Jabesi sì wí fún un pé, “Fún wa ní ọjọ́ méje kí àwa lè rán oníṣẹ́ sí gbogbo Israẹli; àti agbègbè bí ẹni kankan kò bá sì jáde láti gbà wá, àwa yóò fi ara wa fún ọ.”
4 Amo sia: da Gibiaga Solo ea esaloba amoi doaga: i, amola amo sia: ilia sia: noba, dunu ilia da amo sia: nababeba: le hedolo dafawane heawini didigia: i.
Nígbà tí àwọn ìránṣẹ́ náà sì wá sí Gibeah tí ó jẹ́ ìlú Saulu, wọ́n sọ ọ̀rọ̀ wọ̀nyí fún àwọn ènìyàn, gbogbo wọn gbé ohùn wọn sókè, wọ́n sì sọkún.
5 Amogalu, Solo hi bugi sogeanini ea bulamagau amola daeya hi diasu guda: mana didigia: be nababeba: le, e da adole ba: i, “Abuli hamoi? Abuliga dunu huluane da didigia: sala:” Ilia da sia: Ya: ibeseganini gaguli misi sia: amo adodole i.
Nígbà náà gan an ni Saulu padà wá láti pápá, pẹ̀lú màlúù rẹ̀, ó sì béèrè pé, “Kín ni ohun tí ó ṣẹlẹ̀ sí àwọn ènìyàn? Èéṣe tí wọ́n fi ń sọkún?” Nígbà náà ni wọ́n tún sọ fún wọn ọ̀rọ̀ àwọn ọkùnrin Jabesi.
6 Solo da amo sia: nababeba: le, Gode Ea A: silibu Hadigidafa da ema aligila sa: ili amola Solo da bagadewane ougi.
Nígbà tí Saulu sì gbọ́ ọ̀rọ̀ wọn, Ẹ̀mí Ọlọ́run sì bà lé e pẹ̀lú agbára, inú rẹ̀ sì ru sókè.
7 E da bulamagau gawali aduna fane, fofonobone dadamui. Amalu bulamagau dadamui amo huluane sia: adola ahoasu dunu ilima i. Solo da sia: adodola ahoasu dunu ilima, amo bulamagau dadamui agoane Isala: ili fi soge huluanema olelela lama: ne iasi. Amoga ilia da dawa: digima: ne, e da amo sisasu sia: si, “Nowa dunu da Solo amola Sa: miuele elea gegena ahoabe amoga hame madelasea, ilia ohe fofoi amoga da agoane hamomu.” Sia: adola ahoasu dunu ilia da agoane sisia: Isala: ili soge ganodini lai. Isala: ili dunu ilia da Hina Gode Ea ilima adi hamoma: bela: le beda: i, amola ilia huluanedafa Soloma gilisili mafia: i.
Ó sì mú màlúù méjì, ó gé wọn sí wẹ́wẹ́, ó sì rán ẹyẹẹyọ sí gbogbo Israẹli nípa ọwọ́ àwọn ìránṣẹ́ náà, ó ní i ẹ kéde pé, “Èyí ni a ó ṣe sí màlúù ẹnikẹ́ni tí kò bá tọ Saulu àti Samuẹli lẹ́yìn.” Nígbà náà ni ìbẹ̀rù Olúwa sì mú àwọn ènìyàn, wọ́n sì jáde bí ènìyàn kan ṣoṣo.
8 Solo da dunu huluane Bisege moilaiga gegedolesi, dunu da ba: loba 300,000 agoane da Isala: ili dunu amola 30,000 agoane da Yuda dunu agoane ba: i.
Nígbà tí Saulu sì kó wọn jọ ní Beseki, àwọn ọkùnrin Israẹli tí a kà jẹ́ ọ̀kẹ́ mẹ́ẹ̀ẹ́dógún, àwọn ọkùnrin Juda sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dógún.
9 Ilia da Ya: ibese dunu sia: adola misi ilima amane sia: i, “Dia dunuma sia: ma. Aya eso dagobe galu ili da gaga: i ba: mu.” Ya: ibese dunu ilia da amo sia: nababeba: le, ilia da baligili bagade nodoi.
Wọ́n sì sọ fún àwọn ìránṣẹ́ tí ó wá pé, “Sọ fún àwọn ọkùnrin Jabesi Gileadi pé, ní àkókò tí oòrùn bá mú lọ́la, àwa yóò gbà yín sílẹ̀.” Nígbà tí àwọn ìránṣẹ́ náà lọ tí wọ́n sì sọ èyí fún àwọn ọkùnrin Jabesi, inú wọn sì dùn.
10 Amalu ilia da Na: iha: siema amane sia: i, “Aya da dia nini lama: mu, amalu di adi hanai ninima hamomusa: dawa: sea, hamoma: mu.”
Wọ́n sọ fún àwọn ará Jabesi pé, “Àwa yóò fi ara wa fún un yín ní ọ̀la, kí ẹ̀yin kí ó ṣe gbogbo èyí tí ó tọ́ lójú yín sí wa.”
11 Amo gasia, Solo da ea dadi gagui dunu udiana mogi. Golale, hahabedafa, ilia da ha lai diasua hehenaia gugudili sa: ili, A:mone dunu huluane doagala: le, eso dogoa, A:mone dunu huluane da medole legei dagoi ba: i. Dunu hame bogogia: i esafulu, ilia da afagogole, dunu hisu hobeale afia: i.
Ní ọjọ́ kejì Saulu pín àwọn ọkùnrin rẹ̀ sí ipa mẹ́ta, wọ́n sì ya wọ àgọ́ àwọn ará Ammoni ní ìṣọ́ òwúrọ̀, wọ́n sì pa wọ́n títí di ìmóoru ọjọ́. Àwọn tókù wọ́n sì fọ́nká, tó bẹ́ẹ̀ tí méjì wọn kò kù sí ibìkan.
12 Isala: ili dunu ilia da Sa: miuelema amane sia: i, “Dunu amo da Solo ea hina hamoma: ne hame dawa: i amo da habila: ? Amo dunu ninia fanelegemusa: , ninima oule misa!”
Àwọn ènìyàn sọ fún Samuẹli pé, “Ta ni ó béèrè wí pé, Saulu yóò ha jẹ ọba lórí wa? Mú àwọn ọkùnrin náà wá, a ó sì pa wọ́n.”
13 Be Solo da amane sia: i, “Ninia da dunu afae da wali hamedafa fane legemu. Bai wali eso, Hina Gode da Isala: ili dunu gaga: i dagoi.”
Ṣùgbọ́n Saulu wí pé, “A kì yóò pa ẹnikẹ́ni lónìí, nítorí lónìí yìí ni Olúwa ṣiṣẹ́ ìgbàlà ní Israẹli.”
14 Amalu, Sa: miuele da ilima amane sia: i, “Ninia da bu Giliga: lega gilisili, bu Solo da ninia hina bagade asulimu.”
Nígbà náà ni Samuẹli wí fún àwọn ènìyàn pé, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a lọ sí Gilgali, kí a lè fi ẹsẹ̀ Saulu múlẹ̀ bí ọba.”
15 Amaiba: le, ilia da huluane Giliga: le moilaiga asili, hadigi sogea amoi Solo da ilia hina bagade asuli. Ilia da Hahawane Gilisili Olofole Iasu gobele salasu hamonanu, Solo amola Isala: ili dunu huluane ilia da hahawane gilisisu hamoi.
Nítorí náà gbogbo ènìyàn lọ sí Gilgali, wọn sí fi Saulu jẹ ọba ní iwájú Olúwa. Níbẹ̀, ni wọn ti rú ẹbọ ìrẹ́pọ̀ ní iwájú Olúwa, Saulu àti gbogbo Israẹli ṣe àjọyọ̀ ńlá.