< 1 Sa:miuele 10 >

1 Amalu Sa: miuele da olife susuligi di, amo lale Solo ea dialuma da: iya soga: sili, Solo nonogolalu, amane sia: i, “Hina Gode da Ea fi dunu Isala: ili amo ouligima: ne, di mogili gagale ilegei dagoi. Di da Ea dunu fi ouligili amola ha lai dunuga gegenana hasalasisa: besa: le, noga: le gaga: mu. Amola dia da dafawaneyale dawa: ma: ne, Gode da Ea fi dunu gaga: ma: ne dima ilegei dagoi, amo dawa: digisu olelesu ba: ma.
Samuẹli sì mú ìgò kékeré tí òróró wà nínú rẹ̀, ó sì dà á sí orí Saulu. Ó sì fi ẹnu kò ó ní ẹnu, wí pé, “Olúwa kò ha tí fi òróró yàn ọ ní olórí lórí ohun ìní rẹ̀?
2 Dia da na wali yolesisia, Bediamini soge ganodini, Selesa moilaiga amoi La: isele uli dogoia goi dunu aduna gousa: mu. Elea da dima adomu, dougi dia hogolalu amo da ba: i. Be dia ada da dougi yolei amoga bu hame da: i diosa, be diha fawane da: i diosa, amola e da gebewane di abulibaiyale adole ba: la, ‘Na da na manoma adi hamoma: bela: ?’
Bí ìwọ bá kúrò lọ́dọ̀ mi lónìí, ìwọ yóò bá ọkùnrin méjì pàdé lẹ́bàá ibojì Rakeli ní Selsa, ní agbègbè Benjamini. Wọ́n yóò sọ fún ọ pé, ‘Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tí ìwọ jáde lọ láti wá ní wọn tí rí. Nísinsin yìí, baba à rẹ tí dákẹ́ kò ronú nípa wọn mọ́, ó sì ń dààmú nípa à rẹ. Ó ń béèrè, “Kí ni èmi yóò ṣe nípa ọmọ mi?”’
3 Di da amoinini ahoana Dabe sogebia sema ifa baia doaga: mu. Amogai dunu udiana da Bedele moilaiga Godema gobele sala afia: lebe ba: mu. Dunu afae e da goudi mano udiana oule manebe ba: mu. Eno amoea da agi gobei udiana agui ba: mu. Amola osoda da gadofo nodomei esa waini hano di nabane aguni manebe ba: mu.
“Nígbà náà, ìwọ yóò lọ láti ibẹ̀ títí yóò fi dé ibi igi ńlá Tabori. Ọkùnrin mẹ́ta tí wọ́n ń gòkè lọ sọ́dọ̀ Ọlọ́run ní Beteli yóò pàdé rẹ níbẹ̀. Ọ̀kan yóò mú ọmọ ewúrẹ́ mẹ́ta lọ́wọ́, èkejì, ìṣù àkàrà mẹ́ta àti ẹ̀kẹta yóò mú ìgò wáìnì.
4 Ilia da dima hahawane yosia: mu amo ilia agi gobei higagale, digili aduna imunu, amasea amo da dia lama.
Wọ́n yóò kí ọ, wọn yóò sì fún ọ ní ìṣù àkàrà méjì, tí ìwọ yóò gbà lọ́wọ́ wọn.
5 Amalu di da Gode Ea agolo Gibia moilai gadenene amoga asili, Filisidini ilia ha wa: i diasu dialoba amoga doaga: mu. Gibia moilai logo holeiga di da balofede dunu gadigiwane, agoloa gadenene Godema oloda da: iya gobele salalu manebe ba: mu. Ilia da sani baidama, ilibu amola buni fulabosa dusa manebe ba: mu. Ilia da gafosa amola gesami hea: dudalebe ba: mu.
“Lẹ́yìn náà, ìwọ yóò lọ sí òkè Ọlọ́run, níbi tí ẹgbẹ́ ogun àwọn Filistini wà. Bí ìwọ ti ń súnmọ́ ìlú náà, ìwọ yóò bá àwọn wòlíì tí ó tò lọ́wọ̀ọ̀wọ́ bọ̀ láti ibi gíga, pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn, tambori àti fèrè àti haapu níwájú wọn, wọn yóò sì máa sọ àsọtẹ́lẹ̀.
6 Hedolole asili, Gode Ea A: silibu Hadigidafa da dia da: i ganodini aligila sa: ili, Ea di ouligimu, amalu di da ilia gafobe amoga madelale gafomu amola dia da: i da afadenei ba: mu.
Ẹ̀mí Olúwa yóò sì bà lé ọ, ìwọ yóò sì sọtẹ́lẹ̀ pẹ̀lú wọn, ìwọ yóò sì di ẹni ọ̀tọ̀.
7 Amo liligi dima doaga: sea, Gode Ea dima olelebe ba: sea amanewane hamoma.
Bí ìwọ bá ti rí àmì wọ̀nyí, ṣe ohunkóhun tí ọwọ́ rẹ bá bà láti ṣe, nítorí Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ.
8 Di da na bisili Giliga: lega masunu. Amoga na da di gousa: le amola gobele salawane sia: ne gadosu hamomu, amola gilisili sia: ne gadosu hamomu. Amogai eso fesuale ouesalu, amasea na misini dima amane hamoma: ne sia: mu.”
“Lọ ṣáájú mi sí Gilgali. Èmi yóò sọ̀kalẹ̀ tọ̀ ọ́ wá láti rú ẹbọ sísun àti láti rú ẹbọ ìrẹ́pọ̀, ṣùgbọ́n ìwọ gbọdọ̀ dúró fún ọjọ́ méje títí èmi yóò fi wá sí ọ̀dọ̀ rẹ láti sọ fún ọ ohun tí ó yẹ tí ìwọ yóò ṣe.”
9 Solo da Sa: miuele yolesili masunusa: deligi galoba, Gode da Soloma hou eno i. Amola hou huluane Sa: miuele ea Soloma adoi huluane eso amogala doaga: i.
Bí Saulu ti yípadà láti fi Samuẹli sílẹ̀, Ọlọ́run yí ọkàn Saulu padà àti pé gbogbo àmì wọ̀nyí sì wá sí ìmúṣẹ ní ọjọ́ náà.
10 Solo amola ea hawa: hamosu dunu ela da Gibiaga doaga: loba, balofede dunu gilisili dialu da e yosia: i. Be Gode Ea A: silibu da ema aliligila sa: iba: le, e da hedolole fasili balofede dunu oda amola bubuiya gamofogolalebe ba: i.
Nígbà tí wọ́n dé òkè Gibeah náà, àwọn wòlíì tí ó ń tò ní ọ̀wọ̀ọ̀wọ́ pàdé rẹ̀, Ẹ̀mí Ọlọ́run bà lé e nínú agbára, ó sì darapọ̀ bá wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀.
11 Dunu amo da musa: Solo dawa: i, ilia da Solo ea hamobe ba: le amola ilisu adole ba: i, “Gisa ea mano goe da abuli hamobela: ? Solo da balofede dunu hamobela: ?”
Nígbà tí gbogbo àwọn tí ó ti mọ̀ ọ́n tẹ́lẹ̀ rí i tó ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ pẹ̀lú àwọn wòlíì, wọ́n bi ara wọn, “Kí ni ohun tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí ọmọ Kiṣi yìí. Ṣé Saulu wà lára àwọn wòlíì ni?”
12 Dunu amoi fifilasu da amane adole ba: i, “Ma! Balofede dunu oda goe da nowala: ? Dia dawa: loba da ilia eda da nowala: ?” Amaiba: le, sia: ilia da wali sia: da, “Solo amola da dafawane balofede dunu hamobela: ?” amo sia: da amoga mui.
Ọkùnrin kan tí ó ń gbé níbẹ̀ dáhùn pé, “Ta ni baba wọn?” Ó ti di ohun tí a fi ń pa òwe pé, ǹjẹ́ Saulu náà wà lára àwọn wòlíì bí?
13 Solo da bubuluba gagaousa: lai dagoloba, e da agologa, gobele salasu oloda da: iya amoga gado heda: i.
Lẹ́yìn tí Saulu dákẹ́ sísọ àsọtẹ́lẹ̀, ó lọ sí ibi gíga.
14 Solo ea aeyama da Solo amola ea hawa: hamosu dunu ba: beba: le, elama adole ba: i, “Alia da habi lalu?” Solo da dabe adole i, “Ania da dougi hohogola lalu. Ania da dougi hame ba: beba: le, ania da Sa: miuelema ba: la asi.”
Nísinsin yìí, arákùnrin baba Saulu béèrè lọ́wọ́ Saulu àti ìránṣẹ́ rẹ̀ pé, “Níbo ni ẹ lọ?” Ó wí pé, “À ń wá àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,” ṣùgbọ́n nígbà tí a kò rí wọn, a lọ sí ọ̀dọ̀ Samuẹli.
15 Solo ea aeyama da ema adole ba: i, “Amola e da alima adi sia: be?”
Arákùnrin baba Saulu wí pé, “Sọ fún mi ohun tí Samuẹli wí fún un yín.”
16 Solo da bu adole i, “E da anima amane sia: i. Ohe da ba: i dagoi.” Be e da ea aeyamama, Sa: miuele ea Solo da hina bagade dunu hamoma: ma sia: i, amo da ema hame adoi.
Saulu dáhùn pé, “Ó fi dá wa lójú pé wọ́n ti rí àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà.” Ṣùgbọ́n kò sọ fún arákùnrin baba a rẹ̀ ohun tí Samuẹli sọ nípa ọba jíjẹ.
17 Sa: miuele da dunu huluane Misiba moilaiga Hina Godema gilisima: ne sia: i.
Samuẹli pé àwọn ọmọ Israẹli jọ sí iwájú Olúwa ní Mispa.
18 Amalu e da ilima amane sia: i, “Isala: ili ilia Hina Gode da dilima amane sia: sa, ‘Na da dili Idibidi soge ganodini esalu fadegalesi, amola Idibidi dunu ilia dili wadela: lesisa: besa: le, Na da gaga: i dagoi, amola dunu eno fi ilia dili banenesima: ne hamonanu, Na da gaga: i dagoi.
Ó sì wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ, ‘Èmi mú Israẹli jáde wá láti Ejibiti, Èmi sì gbà yín kúrò lọ́wọ́ agbára Ejibiti àti gbogbo ìjọba tí ó ń pọ́n ọn yín lójú.’
19 Na da dia Gode, Na fawane dilima se nabasu amola gasa bagade hou mabe amoga gaga: su, be wali dili da Na higale amola dilia dilisu hina bagade eno lamusa: Nama adole ba: i. Defeawane, amaiba: le dilia fisili dilia fi afae afae amola sosogo fi afae afae ladili Hina Gode midadi gegedoma.’”
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti kọ Ọlọ́run yín, tí ó gbà yín kúrò nínú gbogbo wàhálà àti ìpọ́njú yín. Ẹ̀yin sì ti sọ pé, ‘Rárá, yan ọba kan fún wa.’ Báyìí, ẹ kó ara yín jọ níwájú Olúwa ní ẹ̀yà àti ìdílé yín.”
20 Amalu, Sa: miuele da sosogo fi huluane gegedola misa: ne sia: i, amalu Hina Gode da Bediamini ea sosogo fi ilegei.
Nígbà tí Samuẹli mú gbogbo ẹ̀yà Israẹli súnmọ́ tòsí, ó yan ẹ̀yà Benjamini.
21 Amalu, Sa: miuele da Bediamini egaga fi dunu amo fawane ema gasiguda: ma: ne sia: i, amalu Ma: dili ea sosogo fi amo gadili aliagalesi ba: i. Amalu Ma: dili ea sosogo fi dunu ilia bu gasiguda: i, amola Solo, Gisa ea mano da bu gadili aliagai ba: i. Ilia da Solo hohogola lai, be e hame ba: beba: le,
Ó kó ẹ̀yà Benjamini síwájú ní ìdílé ìdílé, a sì yan ìdílé Matiri. Ní ìparí a sì yan Saulu ọmọ Kiṣi. Ṣùgbọ́n ní ìgbà tí wọ́n wá a, a kò rí i,
22 ilia da Hina Godema adole ba: i, “Dunu eno da ganabela: ?” Hina Gode da adole i, “Solo da liligi sagomusa: lidili gala: su diasuha gadili wamoaligisa.”
bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Olúwa pé, “Ṣé ọkùnrin náà ti wá sí bí ni?” Olúwa sì sọ pé, “Bẹ́ẹ̀ ni ó ti fi ara rẹ̀ pamọ́ láàrín àwọn ẹrù.”
23 Amalalu, ilia da hehenaia asili, dunu aligi dogoa Solo lelu amo oule misi. Amo ilia ba: loba, e da dunu sedadedafa, ela defele da afae hame ba: i.
Wọ́n sáré, wọ́n sì mú un jáde wá. Bí ó ti dúró láàrín àwọn ènìyàn, ó sì ga ju gbogbo àwọn tí ó kù lọ láti èjìká rẹ̀ sókè.
24 Sa: miuele da dunu ilima amane sia: i, “Hina Gode Ea lama: ne ilegei dunu amo da goea! Wegai da dunu niniga da e agoai afae hame.” Dunu huluane da wele sia: i, “Hina bagade da mae bogole, sedagawane fifi ahoanumu da defea!”
Samuẹli sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn pé, “Ṣé ẹ ti ri ọkùnrin tí Olúwa ti yàn? Kò sí ẹnìkan bí i rẹ̀ láàrín gbogbo àwọn ènìyàn.” Nígbà náà àwọn ènìyàn kígbe pé, “Kí ẹ̀mí ọba kí ó gùn!”
25 Sa: miuele da hina bagade ea hawa: hamosu amola eno ouligisu hou bai amo meloa da: iya dedene, sogebi hadigidafa amoga ligisi. Amalu dunu huluane afia: ma: ne sia: i.
Samuẹli ṣàlàyé fún àwọn ènìyàn àwọn ìlànà ìjọba. Ó kọ wọ́n sínú ìwé, ó sì fi lélẹ̀ níwájú Olúwa. Lẹ́yìn náà, Samuẹli tú àwọn ènìyàn ká olúkúlùkù sí ilé e rẹ̀.
26 Solo amolawane bu Gibiaga, buhagi. Gasa bagade dunu oda Gode ili dogoga digilisili gasa i dunu amolawane Solo fisili asi.
Saulu náà padà sí ilé e rẹ̀ ní Gibeah. Àwọn akọni ọkùnrin tí Ọlọ́run ti fi ọwọ́ tọ́ ọkàn wọ́n sì sìn ín.
27 Be dunu oda noga: le hame dadawa: su dunu ilia da amane sia: i, “Dunu goea da ninima adi liligi ida: iwane gala hamoma: bela: ?” Ilia da Soloma higale, igili hahawane udigili iasu liligi afae ema hame gaguli misi.
Ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Beliali wí pé, “Báwo ni ọkùnrin yìí yóò ti ṣe gbà wá?” Wọ́n kẹ́gàn rẹ̀, wọn kò sì mú ẹ̀bùn wá fún un, ṣùgbọ́n Saulu fọwọ́ lérán.

< 1 Sa:miuele 10 >