< 1 Hina 18 >

1 Amalalu, ode osodayale gibu hame daha eso agoanega, Hina Gode da Ilaidiama amane sia: i, “Di asili, hina bagade A: iha: bema doaga: ma! Amasea, Na da gibu iasimu.”
Ó sì ṣe, lẹ́yìn ọjọ́ púpọ̀, ní ọdún kẹta, ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Elijah wá pé, “Lọ, kí o sì fi ara rẹ̀ hàn fún Ahabu, èmi yóò sì rọ òjò sórí ilẹ̀.”
2 Amaiba: le, Ilaidia da muni asi. Samelia soge ganodini, esoiba: le, ha: i da baligili bagadedafa ba: i.
Bẹ́ẹ̀ ni Elijah lọ fi ara rẹ̀ han Ahabu. Ìyàn ńlá sì mú ní Samaria,
3 Amaiba: le, A:iha: be da hina bagade diasu ouligisu dunu Oubadaiama, ema misa: ne sia: i. (Oubadaia da noga: le Hina Godema nodone sia: ne gadosu dawa: i.
Ahabu sì ti pe Obadiah, ẹni tí ń ṣe olórí ilé rẹ̀. Obadiah sì bẹ̀rù Olúwa gidigidi.
4 Yesebele da Hina Gode Ea balofede dunu ili gebewane medole legelaloba, Oubadaia da balofede dunu 100 agoane lale, dogoa mogili gilisisu 50 aduna hamone, magufu gelabo aduna ganodini wamoaligimusa: oule asili, ilima ha: i manu amola hano gaguli masu.)
Nígbà tí Jesebeli sì ń pa àwọn wòlíì Olúwa kúrò, Obadiah sì mú ọgọ́rùn-ún wòlíì, ó sì fi wọ́n pamọ́ sínú ihò òkúta, àádọ́ta ní ihò kọ̀ọ̀kan, ó sì fi àkàrà pẹ̀lú omi bọ́ wọn.
5 A: iha: be da Oubadaiama amane sia: i, “Ani ahoa: di! Ania da hano bubuga: su amola hano logo huluane soge ganodini ba: la masunu. Ania da Isala: ili dunu ilia hosi amola miule esalomusa: defele gisi hogola masunu. Amabela: ? Ninia ohe afae da hame medole legei ba: ma: bela: ?”
Ahabu sì ti wí fún Obadiah pé, “Lọ sí gbogbo ilẹ̀ sí orísun omi gbogbo àti sí ilẹ̀ gbogbo. Bóyá àwa lè rí koríko láti gba àwọn ẹṣin àti àwọn ìbáaka là, kí a má bá à ṣòfò àwọn ẹranko pátápátá.”
6 Ela da sia: dalu, ela afae afae hogola masunu soge ilegei. Amalalu, ela da logo higagale asi.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì pín ilẹ̀ tí wọ́n fẹ́ dé láàrín ara wọn, Ahabu gba ọ̀nà kan lọ, Obadiah sì gba ọ̀nà mìíràn lọ.
7 Oubadaia da logoga ahoanoba, hedolowane Ilaidia ba: i. E da ea odagi dawa: beba: le, ea midadi gududafa beguduli, amane adole ba: i, “Hina! Amo da dila: ?”
Bí Obadiah sì ti ń rìn lọ, Elijah sì pàdé rẹ̀. Obadiah sì mọ̀ ọ́n, ó dojúbolẹ̀, ó sì wí pé, “Ǹjẹ́ ìwọ ni nítòótọ́, Elijah, olúwa mi?”
8 E bu adole i, “Dafawane! Na da Ilaidia wea! Di asili, dia hina bagade ema na da guiguda: esala: ba: ya adoma!”
Elijah sì dá a lóhùn pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, lọ kí o sọ fún olúwa rẹ pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’”
9 Oubadaia da amane adole i, “Na da adi hamobela: ? Dia da abuliba: le na hina bagade A: iha: be, ea na fane legema: ne logo fodosala: ?
Obadiah sì béèrè pé, “Ẹ̀ṣẹ̀ kí ni mo ha dá tí ìwọ fi ń fi ìránṣẹ́ rẹ lé Ahabu lọ́wọ́ láti pa?
10 Dia Hina Gode Esala amo Ea Dioba: le na da dafawane ilegele sia: sa. A: iha: be da osobo bagadega fifi asi gala huluane amo ganodini, di hogoi helei. Soge fi ouligisu dunu afae da di da ea soge ganodini hame esala sia: ne iasu ianoba, A:iha: be da amo hina bagade, e da di hamedafa ba: i, amo dafawane ilegele sia: musa: sia: i.
Mo mọ̀ dájú pé bí Olúwa Ọlọ́run rẹ ti ń bẹ, kò sí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan tí olúwa mi kò ti rán ènìyàn lọ láti wò ọ́. Àti nígbà tí orílẹ̀-èdè tàbí ìjọba kan bá wí pé o kò sí, òun a sì mú kí wọ́n búra wí pé wọn kò rí ọ.
11 Amaiba: le, di da abuliba: le nama di da goega: i esala, amane ema sia: na masa: ne sia: bela: ?
Ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ìwọ wí fún mi pé kí n lọ sọ́dọ̀ olúwa mi, kí n sì wí pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’
12 Na da ahoasea, amola Hina Gode Ea A: silibu da di eno hame dawa: sogega oule ahoasea, na da adi hamoma: bela: ? Amane hamosea, na da A: iha: bema, di da goega: i esala amo adole, e da di goega: i esalebe hame ba: sea, na medole legemu. Di bu dawa: ma! Na goi fonobahadiga ganini, Hina Godema noga: le nodone sia: ne gadosu dawa: i.
Èmi kò sì mọ ibi tí ẹ̀mí Olúwa yóò gbé ọ lọ nígbà tí mo bá fi ọ́ sílẹ̀. Bí mo bá lọ, tí mo sì sọ fún Ahabu, tí kò sì rí ọ, òun a sì pa mí. Síbẹ̀ èmi ìránṣẹ́ rẹ bẹ̀rù Olúwa láti ìgbà èwe mi wá.
13 Yesebele da Hina Gode Ea balofede dunu ili gebewane medole legelaloba, na da balofede dunu 100 agoane lale, dogoa mogili gilisisu idi 50 aduna hamone, magufu gelabo aduna ganodini wamoaligimusa: oule asili, ilima ha: i manu amola hano gaguli masu. Amo di da hame nabibala: ?
Ṣé Olúwa mi kò ha ti gbọ́ ohun tí mo ṣe nígbà tí Jesebeli ń pa àwọn wòlíì Olúwa? Mo fi ọgọ́rùn-ún wòlíì Olúwa pamọ́ sínú ihò òkúta méjì, àràádọ́ta ní ọ̀kọ̀ọ̀kan, mo sì fi omi àti oúnjẹ bọ́ wọn.
14 Amaiba: le, di da abuli na hina bagadema, di da goega: i esala: ba: ya adoma: ne, nama sia: sala: ? E da na medole legemu!”
Ìwọ sì sọ fún mi nísinsin yìí pé, kí n tọ olúwa mi lọ pé, ‘Elijah ń bẹ níhìn-ín.’ Òun a sì pa mí!”
15 Ilaidia da bu adole i, “Na da Hina Gode Bagadedafa Esala amo Ea hawa: hamonana. Amola na da Ea Dioba: le dafawane ilegele sia: sa. Na da wali esoga, hina bagadema odagi olemu.”
Elijah sì wí pé, “Bí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti wà, ẹni tí èmi ń sìn, nítòótọ́ èmi yóò fi ara mi hàn fún Ahabu lónìí.”
16 Amaiba: le, Oubadaia da hina bagade A: iha: bema asili, ema Ilaidia da esala: ba: ya adoi. Amalu, A:iha: be da Ilaidia gousa: musa: asi.
Bẹ́ẹ̀ ni Obadiah sì lọ láti pàdé Ahabu, ó sì sọ fún un, Ahabu sì lọ láti pàdé Elijah.
17 A: iha: be da Ilaidia ba: beba: le, amane sia: i, “Agoea esalebe! Di da Isala: ili soge ganodini bidi hamosu dunu oda ilia hamosu bagadewane baligisa.”
Nígbà tí Ahabu sì rí Elijah, ó sì wí fún un pé, “Ṣé ìwọ nìyìí, ìwọ tí ń yọ Israẹli lẹ́nu?”
18 Ilaidia da bu adole i, “Na da bidi hamosu dunudafa hame. Be di amola dia ada alia da bidi hamosu dunu. Di da Hina Gode Ea hamoma: ne sia: i amo mae nabawane hamone, ogogole ‘gode’ Ba: ile agoaila hahamoi amoma nodone sia: ne gadolala.
Elijah sì dá a lóhùn pé, “Èmi kò yọ Israẹli lẹ́nu, bí kò ṣe ìwọ àti ilé baba rẹ. Ẹ ti kọ òfin Olúwa sílẹ̀, ẹ sì ń tọ Baali lẹ́yìn.
19 Waha Isala: ili dunu huluane na gousa: musa: , Gamele Goumi amoga misa: ne sia: ma. Ilia da Ba: ile balofede dunu 450 agoane amola ogogole uda ‘gode’ Asila ea balofede dunu 400 agoane amo da hina bagade uda Yesebele ea fuligala: be, amo huluane oule misa.”
Nísinsin yìí kó gbogbo Israẹli jọ láti pàdé mi lórí òkè Karmeli. Àti kí o sì mú àádọ́ta lé ní irinwó àwọn wòlíì Baali àti irinwó àwọn wòlíì òrìṣà Aṣerah tí wọ́n ń jẹun ní tábìlì Jesebeli.”
20 Amaiba: le, A:iha: be da Isala: ili dunu huluane amola Ba: ile balofede dunu huluane, Gamele Goumia gilisima: ne sia: i.
Bẹ́ẹ̀ ni Ahabu ránṣẹ́ sí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli, ó sì kó àwọn wòlíì jọ sí orí òkè Karmeli.
21 Ilaidia da dunu huluanema asili, amane sia: i, “Dilia da habo wali seda ‘gode’ aduna elama fa: no bobogemusa: dadawa: loma: bela: ? Dilia da Hina Gode da Godedafa dawa: sea, Ema nodone sia: ne gadoma! Be dilia da Ba: ile da Godedafa dawa: sea, ema nodone sia: ne gadoma!” Be Isala: ili dunu da sia: afae hamedafa sia: i.
Elijah sì lọ síwájú gbogbo àwọn ènìyàn, ó sì wí pé, “Yóò ti pẹ́ tó tí ẹ̀yin yóò máa ṣiyèméjì? Bí Olúwa bá ni Ọlọ́run, ẹ máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn, ṣùgbọ́n bí Baali bá ni Ọlọ́run, ẹ máa tọ̀ ọ́ lẹ́yìn.” Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà kò sì wí ohun kan.
22 Amalalu, Ilaidia da amane sia: i, “Na fawane da Hina Gode Ea balofede dunudafa esala. Be Ba: ile ea balofede dunu da 450 agoane esala.
Nígbà náà ni Elijah wí fún wọn pé, “Èmi nìkan ṣoṣo ni ó kù ní wòlíì Olúwa, ṣùgbọ́n, àádọ́ta lé ní irinwó ni wòlíì Baali.
23 Bulamagau gawali aduna gaguli misa! Ba: ile balofede dunu ilia da afae lale, medole, dasega: le, lalu habei da: iya ligisima. Be lalu mae ulagima. Na da bulamagau eno amoga ilia hamoi amo defele hamomu.
Ẹ fún wa ní ẹgbọrọ akọ màlúù méjì. Jẹ́ kí wọn kí ó sì yan ẹgbọrọ akọ màlúù kan fún ara wọn, kí wọn kí ó sì gé e sí wẹ́wẹ́, kí wọn kí ó sì tò ó sí orí igi, kí wọn kí ó má ṣe fi iná sí i. Èmi yóò sì tún ẹgbọrọ akọ màlúù kejì ṣe, èmi yóò sì tò ó sórí igi, èmi kì yóò sì fi iná sí i.
24 Amalu, Ba: ile balofede dunu da ilia ‘gode’ma sia: ne gadoma: ma. Amola na da Hina Godema sia: ne gadomu. Amalu, nowa ea hahamoi lalu nene gala: be ba: sea, amo ilia ‘gode’ da Godedafa esalebe dawa: mu.” Dunu huluane da amo hamomu hou hahawane nababeba: le, wele sia: i.
Nígbà náà ẹ ó sì ké pe orúkọ àwọn Ọlọ́run yín, èmi yóò sì ké pe orúkọ Olúwa. Ọlọ́run náà tí ó fi iná dáhùn, òun ni Ọlọ́run.” Nígbà náà ni gbogbo àwọn ènìyàn náà sì wí pé, “Ohun tí ìwọ sọ dára.”
25 Ilaidia da Ba: ile balofede dunuma amane sia: i, “Dilia da dunu bagohameba: le, dili hidadea, bulamagau gawali lale, hahamoma. Dilia ‘gode’ma sia: ne gadoma, be lalu habei mae ulagisima.”
Elijah sì wí fún àwọn wòlíì Baali wí pé, “Ẹ yan ẹgbọrọ akọ màlúù kan fún ara yín, kí ẹ sì tètè kọ́ ṣe é, nítorí ẹ̀yin pọ̀. Ẹ ké pe orúkọ àwọn ọlọ́run yín, ṣùgbọ́n ẹ má ṣe fi iná sí i.”
26 Ilia da bulamagau gawali amo da ilima gaguli misi, amo lale hahamoi. Amalu, Ba: ilema sia: ne gadolalobawane, esomogoa doaga: i. Ilia da amane wele sia: i, “Ba: ile! Ba: ile! Ninia sia: ne gadobe nabima: i!” Amola, ilia da oloda ilia gagili, amo sisiga: le, gagafodudalu. Be amomane, Ba: ile da ilima dabe hame adole i.
Nígbà náà ni wọ́n sì mú ẹgbọrọ akọ màlúù náà, tí a ti fi fún wọn, wọ́n sì ṣe é. Nígbà náà ni wọ́n sì ké pe orúkọ Baali láti òwúrọ̀ títí di ọ̀sán gangan wí pé, “Baali! Dá wa lóhùn!” Wọ́n sì ń kégbe. Ṣùgbọ́n kò sí ìdáhùn; kò sí ẹnìkan tí ó sì dáhùn. Wọ́n sì jó yí pẹpẹ náà ká, èyí tí wọ́n tẹ́.
27 Esomogoadafa, Ilaidia da iliba: le lalasogole oufesega: nu. E amane sia: i, “Bu ha: giwane sia: ne gadoma! E da ‘gode’! E da olobolala ganumu o baeya sowana ganumu. O e da logoba: le asi ganumu. O e da golai diala ganumu. Amo didilisima!”
Ní ọ̀sán gangan, Elijah bẹ̀rẹ̀ sí ń fi wọ́n ṣe ẹlẹ́yà ó sì wí pé, “Ẹ kígbe lóhùn rara Ọlọ́run sá à ni òun! Bóyá ó ń ṣe àṣàrò, tàbí kò ráyè, tàbí ó re àjò. Bóyá ó sùn, ó yẹ kí a jí i.”
28 Amaiba: le, balofede dunu da bu ha: giwane sia: ne gadole amola ilia hou defele, ili gobele gobihei amola nusi amoga fofa: ginanobawane, maga: me da a: idafia: i.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì kígbe lóhùn rara, wọ́n sì fi ọ̀bẹ àti ọ̀kọ̀ ya ara wọn gẹ́gẹ́ bí ìṣe wọn, títí tí ẹ̀jẹ̀ fi tú jáde ní ara wọn.
29 Ilia da dadoula sisiga: sa lafia: lalobawane, baloga doaga: i. Be dabe adole iasu sia: da afae hame nabi.
Nígbà tí ọjọ́ yẹ àtàrí, wọ́n sì ń fi òmùgọ̀ sọtẹ́lẹ̀ títí di àkókò ìrúbọ àṣálẹ́, ṣùgbọ́n kò sí ohùn, kò sì ṣí ìdáhùn, kò sì ṣí ẹni tí ó kà á sí.
30 Amalalu, Ilaidia da dunu huluanema amane sia: i, “Nama gadenena misa.” Ilia da Ilaidiama gilisila misi. E da Hina Gode Ea oloda mugului, amo bu hahamoi.
Nígbà náà ni Elijah wí fún gbogbo àwọn ènìyàn náà pé, “Ẹ súnmọ́ mi.” Wọ́n sì súnmọ́ ọn, ó sì tún pẹpẹ Olúwa tí ó ti wó lulẹ̀ ṣe.
31 E da gele fagoyale gala lai. Amo gele afae afae da Ya: igobe (Hina Gode da ema Isala: ili dio asuli) amo ea mano afae afae dawa: ma: ne, lai.
Elijah sì mú òkúta méjìlá, ọ̀kọ̀ọ̀kan fún ẹ̀yà ọmọ Jakọbu kan, ẹni tí ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ wá wí pé, “Israẹli ni orúkọ rẹ̀ yóò máa jẹ́.”
32 Amo gelega, e da Hina Godema nodone sia: ne gadosu oloda bu hahamoi. Oloda sisiga: le, e da hano logo amoga hano soga: sali amo nabai defei da 15 lida.
Ó sì tẹ́ pẹpẹ pẹ̀lú àwọn òkúta wọ̀nyí ní orúkọ Olúwa, ó sì wa yàrá yí pẹpẹ náà ká, tí ó lè gba ìwọ̀n òsùwọ̀n irúgbìn méjì.
33 Amalu, e da oloda da: iya, lalu habei ligisili, bulamagau dasega: le, fofonobone dadamuni ligisi. E amane sia: i, “Dilia da osoboga hamoi ofodo bagade biyaduyale amoga hano dili, amo bulamagau gobele salimu amo da: iya amola lalu habei da: iya sogaga: la: ma.” Ilia da amo defele hamoi.
Ó sì to igi náà dáradára, ó sì ké ẹgbọrọ akọ màlúù náà wẹ́wẹ́, ó sì tò ó sórí igi. Nígbà náà ni ó sì wí fún wọn wí pé, “Ẹ fi omi kún ìkòkò mẹ́rin, kí ẹ sì tu sórí ẹbọ sísun àti sórí igi náà.”
34 E amane sia: i, “Bu hamoma!” Ilia da amane hamoi. E amane sia: i, “Bu hamoma!” Amola ilia da amane hamoi.
Ó sì wí pe, “Ẹ ṣe é ní ìgbà kejì.” Wọ́n sì ṣe é ní ìgbà kejì. Ó sì tún wí pé, “Ṣe é ní ìgbà kẹta.”
35 Hano da gudu sa: ili, oloda sisiga: le, hano logo nabalesi.
Omi náà sì sàn yí pẹpẹ náà ká, ó sì fi omi kún yàrá náà pẹ̀lú.
Ó sì ṣe, ní ìrúbọ àṣálẹ́, wòlíì Elijah sì súnmọ́ tòsí, ó sì gbàdúrà wí pé, “Olúwa, Ọlọ́run Abrahamu, Isaaki àti Israẹli, jẹ́ kí ó di mí mọ̀ lónìí pé ìwọ ni Ọlọ́run ní Israẹli àti pé èmi ni ìránṣẹ́ rẹ, àti pé mo ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí nípa àṣẹ rẹ.
37 Baloga, ilia gobele salasu hamoma: ne ilegebe, balofede Ilaidia da oloda amoga asili, amane sia: ne gadoi, “Hina Gode! A: ibalaha: me amola Aisage amola Ya: igobe ilia Gode! Di da Isala: ili Godedafa, amola na da Dia hawa: hamosu dunu, amola na wali hamoi da Dia hamoma: ne sia: beba: le hamoi, Isala: ili dunu da amo huluane dafawaneyale dawa: ma: ne, Dia na adole ba: su sia: ne gadosu amoma dabe adole ima. Hina Gode! Nama bu adole ima. Isala: ili dunu da Di, Hina Gode, da Godedafa amola Di da ili Dima bu hiougilala, amo ilia da dawa: ma: ne, na sia: ne gadosu amo dabe adole ima.”
Gbọ́ ti èmi, Olúwa, gbọ́ ti èmi, kí àwọn ènìyàn wọ̀nyí lè mọ̀ pé ìwọ Olúwa ni Ọlọ́run àti pé ìwọ tún yí ọkàn wọn padà.”
38 Hina Gode da lalu gudu sanasi. Lalu da gobele salasu bulamagau amola lalu habei amola gele amola osobo huluane nene dagoi. Amola hano amo hano logo ganodini dialu amo huluane hafoga: i dagoi ba: i.
Nígbà náà ni iná Olúwa bọ́ sílẹ̀, ó sì sun ẹbọ sísun náà àti igi, àti àwọn òkúta, àti erùpẹ̀, ó sì tún lá omi tí ń bẹ nínú yàrá náà.
39 Dunu huluane da amo hou ba: beba: le, ilisu osoba gala: la sa: i. Ilia amane wele sia: i, “Hina Gode da Godedafa! Hina Gode Hisu da Godedafa!”
Nígbà tí gbogbo àwọn ènìyàn sì rí èyí, wọ́n da ojú wọn bolẹ̀, wọ́n sì kígbe pé, “Olúwa, òun ni Ọlọ́run! Olúwa, òun ni Ọlọ́run!”
40 Ilaidia da amane hamoma: ne sia: i, “Ba: ile balofede dunu gagulaliligima! Dunu afae da maedafa hobeama: ma!” Isala: ili dunu da Ba: ile balofede dunu huluane gagulaliligi. Amola Ilaidia da ili oule, Gaisione Hanoga sa: ili, ili huluane fane lelegei.
Nígbà náà ni Elijah sì pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ mú àwọn wòlíì Baali. Ẹ má ṣe jẹ́ kí ọ̀kan nínú wọn kí ó sálọ!” Wọ́n sì mú wọn, Elijah sì mú wọn sọ̀kalẹ̀ sí àfonífojì Kiṣoni, ó sì pa wọ́n níbẹ̀.
41 Amalalu, Ilaidia da hina bagade A: iha: bema amane sia: i, “Waha ha: i namasa! Na da gibu bagade olamabe naba!”
Elijah sì wí fún Ahabu pé, “Lọ, jẹ, kí o sì mu, nítorí ìró ọ̀pọ̀lọpọ̀ òjò ń bọ̀.”
42 A: iha: be da ha: i na ahoanoba, Ilaidia da Gamele Goumi da: iya heda: le, beguduli, osoboga muguni adoba dialuma bugi.
Bẹ́ẹ̀ ni Ahabu gòkè lọ láti jẹ àti láti mu. Ṣùgbọ́n Elijah gun orí òkè Karmeli lọ ó sì tẹríba, ó sì fi ojú rẹ̀ sí agbede-méjì eékún rẹ̀.
43 E da ea hawa: hamosu dunuma amane sia: i, “Di da asili, hano wayabo bagade amoga ba: le gama!” Ea hawa: hamosu dunu da amo ba: la asili, bu misini, amane sia: i, “Na da liligi hamedafa ba: i.” Ilaidia da ema fesuale agoane ba: la afufuma: ne sia: i.
Ó sì wí fún ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ pé, “Lọ, kí o sì wo ìhà Òkun, òun sì gòkè lọ, ó sì wò.” Ó sì wí pé, “Kò sí nǹkan níbẹ̀.” Ó sì wí pé, “Tún lọ nígbà méje.”
44 E da afufulala fesu amoga ba: la asi, bu misini, amane sia: i, “Na da mobi fonobahadi, dunu ea lobo agoai, amo baligili hame, be agoai fawane hano wayabo gudunini gado heda: lebe ba: i.” Ilaidia da ea hawa: hamosu dunuma amane sia: i, “hina bagade A: iha: bema asili, ea masunu logo gibuga ga: sa: besa: le, ea ‘sa: liode’ lale, amo da: iya fila heda: le, hi diasua hedolo masa: ne sia: ma.”
Nígbà keje, ìránṣẹ́ náà sì wí pé, “Àwọsánmọ̀ kékeré kan dìde láti inú Òkun, gẹ́gẹ́ bí ọwọ́ ènìyàn.” Elijah sì wí pé, “Lọ, kí o sọ fún Ahabu pé, ‘Di kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ, kí o sì sọ̀kalẹ̀ lọ, kí òjò ó má ba à dá ọ dúró.’”
45 Fonobahadi aligili, mu da mobiga gasili gala: i ba: i, amola fo da muni misi amola gibu bagade da muni sa: i. A: iha: be da ea ‘sa: liode’ da: iya fila heda: le, Yeseliele moilai bai bagadega buhagi.
Ó sì ṣe, nígbà díẹ̀ sí i, ọ̀run sì ṣú fún àwọsánmọ̀, ìjì sì dìde, òjò púpọ̀ sì rọ̀, Ahabu sì gun kẹ̀kẹ́ lọ sí Jesreeli.
46 Hina Bagade Gode Ea gasa da misini, Ilaidiama doaga: i. Ilaidia da ea abula hina: bulu ga: sua ha: gidafa idiniginanu, A:iha: be fa: nonesilalu, ea bisili hehenaiya ahoana, Yeseliele amoma doaga: i.
Agbára Olúwa sì ń bẹ lára Elijah; ó sì di àmùrè ẹ̀gbẹ́ rẹ, ó sì sáré níwájú Ahabu títí dé Jesreeli.

< 1 Hina 18 >