< 1 Hina 15 >

1 Isala: ili fi ilia hina bagade Yelouboua: me da ode18 ouligilalu, Abaidia da Yuda fi ilia hina bagade hamoi.
Ní ọdún kejìdínlógún ìjọba Jeroboamu ọmọ Nebati, Abijah jẹ ọba lórí Juda,
2 E da ode udiana Yelusaleme moilai bai bagadega esala, Yuda fi ouligilalu. Ea ame da Ma: iaga (A: basolome ea idiwi).
ó sì jẹ ọba ní ọdún mẹ́ta ní Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Maaka, ọmọbìnrin Absalomu.
3 E da ea ada ea wadela: i hou hamosu defele hamoi. Ea ada aowa Da: ibidi da mae fisili, Hina Godema fa: no bobogelalu. Be e da amo defele hame hamoi.
Ó sì rìn nínú gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí baba rẹ̀ ti dá ṣáájú rẹ̀; ọkàn rẹ̀ kò sì pé pẹ̀lú Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ọkàn Dafidi baba ńlá rẹ̀ ti ṣe.
4 Be ea Hina Gode da Da: ibidima asigiba: le, Hina Gode da Abaidiama e bagia Yuda fi ilia hina dunu hamoma: ne amola Yelusaleme ganodini esaloma: ne amola gaga: ma: ne, Abaidiama mano i.
Ṣùgbọ́n, nítorí i Dafidi Olúwa Ọlọ́run rẹ̀ fún un ní ìmọ́lẹ̀ kan ní Jerusalẹmu nípa gbígbé ọmọ rẹ̀ ró láti jẹ ọba ní ipò rẹ̀ àti láti fi ìdí Jerusalẹmu múlẹ̀.
5 Hina Gode da agoane hamoi bai Da: ibidi da Ema nodoma: ne hamoi amola Ema Ea hamoma: ne sia: i amoga hame nabasu hou hame hamoi. E da hame nabasu hou afae fawane hamoi. Amo e da Iulaia (Hidaide dunu) ema fawane wadela: le hamoi.
Nítorí tí Dafidi ṣe èyí tí ó dára ní ojú Olúwa, tí kò sì kùnà láti pa gbogbo èyí tí Olúwa pàṣẹ fún un mọ́ ní ọjọ́ ayé rẹ̀ gbogbo; bí kò ṣe ní kìkì ọ̀ràn Uriah ará Hiti.
6 Gegesu mui amo da Lihouboua: me amola Yelouboua: me ela ouligibi ganodini ba: i, amo da Abaidia ea esalusu amo galu gebewane gegenanusu.
Ogun sì wà láàrín Rehoboamu àti Jeroboamu ní gbogbo ọjọ́ ayé Abijah.
7 Amola Abaidia ea hamonanusu hou huluane da “Yuda hina bagade ilia Hamonanusu Meloa’ amo ganodini dedene legei.
Ní ti ìyókù ìṣe Abijah, àti gbogbo èyí tí ó ṣe, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda? Ogun sì wà láàrín Abijah àti Jeroboamu.
8 Abaidia da bogobeba: le, Da: ibidi Moilai Bai Bagade amo ganodini uli dogone sali. Amola, egefe A: isa da e bagia, Yuda fi ilia hina bagade hamoi.
Abijah sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín ní ìlú Dafidi. Asa ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
9 Isala: ili hina bagade Yelouboua: me da ode 20 Isala: ili soge ouligilalu, A:isa da Yuda fi ilia hina bagade hamoi.
Ní ogún ọdún Jeroboamu ọba Israẹli, Asa jẹ ọba lórí Juda,
10 E da Yelusaleme moilai bai bagadega esala, ode 41agoanega, Isala: ili fi ouligilalu. Ea aya: da Ma: iga (A: basalome ea idiwi).
Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu ní ọdún mọ́kànlélógójì. Orúkọ ìyá ńlá rẹ̀ sì ni Maaka, ọmọbìnrin Absalomu.
11 A: isa da Hina Gode Ea nodoma: ne, ea aowa Da: ibidi ea hamoi amo defele hamoi.
Asa sì ṣe èyí tí ó dára lójú Olúwa, bí Dafidi baba rẹ̀ ti ṣe.
12 E da Yuda Soge ganodini hina: da: iga bidi lasu uda amola dunu huluane amo da ogogole ‘gode’ loboga hahamoi, ilima nodone sia: ne gadolalu, amo huluane gadili sefafasi. A: isa da ogogole loboga hamoi ‘gode’ ea adalalia hahamoi, amo huluane gadili fadegale fafasi.
Ó sì mú àwọn ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà kúrò ní ilẹ̀ náà, ó sì kó gbogbo ère tí àwọn baba rẹ̀ ti ṣe kúrò.
13 A: isa da ea aya: Ma: iga (e da ‘uda hina bagade eme’, ilia da sia: su) ea sogebi amo fadegai. Bai Ma: iga da gogosiasu bagade liligi (mano lama: ne ogogole uda ‘gode’, Asila ema sia: ne gadosu-amo agoaila) amo hahamoi. A: isa da amo loboga hamoi liligi amo dadamuni sanawene, Gidalone Fago amoga ulagili sali.
Ó sì mú Maaka ìyá ńlá rẹ̀ kúrò láti máa ṣe ayaba, nítorí tí ó yá ère kan fún Aṣerah òrìṣà rẹ̀. Asa sì ké ère náà lulẹ̀, ó sì jó o ní àfonífojì Kidironi.
14 A: isa da ogogole ‘gode’ma nodone sia: ne gadosu sogebi bagohame mugului. Be mogili hame wadela: lesi. Be e da Hina Godema mololewane fa: no bobogelalu.
Ṣùgbọ́n kò mú àwọn ibi gíga kúrò, síbẹ̀ ọkàn Asa pé pẹ̀lú Olúwa ní ọjọ́ ayé rẹ̀ gbogbo.
15 E da Debolo diasu ganodini, liligi huluane ea ada da Godema ilegele i, amola gouli amola silifa liligi e da hisu Godema ilegele i, amo huluane Debolo diasu ganodini ligisi.
Ó sì mú wúrà àti fàdákà àti àwọn ohun èlò tí òun àti baba rẹ̀ ti yà sí mímọ́ wọ ilé Olúwa.
16 Yuda hina bagade A: isa amola Isala: ili hina bagade Ba: iasia da ela ouligibi amo ganodini, gebewane gegenanusu.
Ogun sì wà láàrín Asa àti Baaṣa ọba Israẹli ní gbogbo ọjọ́ ayé wọn.
17 Ba: iasia da Yuda soge doagala: le, golili sa: ili, e da Yuda gadili ahoasu logo ga: ma: ne, muni La: ima moilai gagili sali.
Baaṣa, ọba Israẹli sì gòkè lọ sí Juda, ó sì kọ́ Rama láti má jẹ́ kí ẹnikẹ́ni jáde tàbí wọlé tọ Asa ọba lọ.
18 Amaiba: le, hina bagade A: isa da silifa amola gouli huluane Debolo amola hina bagade diasu amo ganodini hame lai dialebe ba: i, amo lale, ea eagene ouligisu dunu ilia Dama: saga: se moilai, Silia hina bagade Beneha: ida: de (Da: balimone egefe amola Hisione ea aowa) ema imunusa: gaguli masa: ne sia: i. Amola e da ilia ema amane sia: ma: ne sia: si,
Nígbà náà ni Asa mú gbogbo fàdákà àti wúrà tí ó kù nínú ìṣúra ilé Olúwa àti ìṣúra ilé ọba. Ó sì fi lé àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ lọ́wọ́, ó sì rán wọn lọ sí ọ̀dọ̀ Beni-Hadadi ọmọ Tabrimoni, ọmọ Hesioni ọba Siria tí ó ń gbé ní Damasku.
19 “Ani da anianini, ania adalali defele, dogolegemu da defea. Amo silifa amola gouli da digili hahawane udigili iasu. Wali di amola Isala: ili hina bagade Ba: iasia alialisu gousa: su hamoi amo damuma. Amasea, e da ea dadi gagui dunu na soge ganodini asunasili esala, amo fadegale fasima.”
Ó sì wí pé, “Jẹ́ kí májẹ̀mú kí ó wà láàrín èmi àti ìwọ, bí ó sì ti wà láàrín baba mi àti baba rẹ. Wò ó, Èmi rán ọrẹ fàdákà àti wúrà sí ọ. Ǹjẹ́ nísinsin yìí, da májẹ̀mú rẹ pẹ̀lú Baaṣa, ọba Israẹli, kí ó lè lọ kúrò lọ́dọ̀ mi.”
20 Hina bagade Beneha: ida: de da A: isa ea sia: i hahawane ba: i. Amaiba: le, e da ea dadi gagui wa: i ouligisu dunu amola dadi gagui dunu ilia Isala: ili moilale gagale fi amo ilima doagala: ma: ne, asunasi. Ilia da Aidione, Da: ne, A:ibele Bede Ma: iga moilale gagai, amola Ga: lili Hano Wayabo beba: le soge amola Na: fadalai soge huluane fefedele lai.
Beni-Hadadi gba ti Asa ọba, ó sì rán àwọn alágbára olórí ogun rẹ̀ sí àwọn ìlú Israẹli. Ó sì ṣẹ́gun Ijoni, Dani àti Abeli-Beti-Maaka, àti gbogbo Kinnereti pẹ̀lú gbogbo ilẹ̀ Naftali.
21 Hina bagade Ba: iasia da amo hamoi sia: nababeba: le, La: ima moilai gagili salalu, amo yolesili, Desa moilai bai bagadega asi.
Nígbà tí Baaṣa sì gbọ́ èyí, ó sì ṣíwọ́ kíkọ́ Rama, ó sì lọ kúrò sí Tirsa.
22 Amalalu, hina bagade A: isa da Yuda soge ganodini amo dunu huluanedafa da igi amola gele amoga Ba: iasia da La: ima gagili sali, amo gaguli masa: ne sia: si. Amo liligi lale, A:isa da Bediamini soge moilai Giba amola Misiba moilai, amo gagili sali.
Nígbà náà ni Asa ọba kéde ká gbogbo Juda, kò dá ẹnìkan sí, wọ́n sì kó òkúta Rama kúrò àti igi rẹ̀, tí Baaṣa fi kọ́lé. Asa ọba sì fi wọ́n kọ́ Geba ti Benjamini àti Mispa.
23 Hou huluane hina bagade A: isa hamoi, ea gesa: i hamonanu amola moilai bai bagade e da gagili sali, amo huluane da “Yuda hina bagade ilia Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei. Be e da da: i hamobeba: le, e da olobeba: le, emo gasuga: igi.
Ní ti ìyókù gbogbo ìṣe Asa, àti gbogbo agbára rẹ̀, àti gbogbo ohun tí ó ṣe, àti àwọn ìlú tí ó kọ́, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda? Ṣùgbọ́n, ní ìgbà ogbó rẹ̀, ààrùn ṣe é ní ẹsẹ̀ rẹ̀.
24 A: isa da bogobeba: le, ilia da e hina bagade uli dogosu sogebi, Da: ibidi Moilai Bai Bagade, amo ganodini dogone sali. Amola egefe Yihosiafa: de e da A: isa e bagia hina bagade hou lai.
Asa sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ ní ìlú Dafidi baba rẹ̀. Jehoṣafati ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
25 Yuda hina bagade A: isa da ode ageyadu Yuda fi ouligilalu, Na: ida: be (hina bagade Yelouboua: me egefe) e da Isala: ili ouligisu hina bagade hamoi. E da ode aduna ouligilalu.
Nadabu ọmọ Jeroboamu sì jẹ ọba lórí Israẹli ní ọdún kejì Asa ọba Juda, ó sì jẹ ọba lórí Israẹli ní ọdún méjì.
26 E da ea ada ea hou defele, Hina Godema wadela: le hamoi. Amola e da Isala: ili dunu wadela: le hamoma: ne, oule asi.
Ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, ó sì rìn ní ọ̀nà baba rẹ̀ àti nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, èyí tí ó mú Israẹli dá.
27 Ba: iasia (Isaga fi dunu amola Ahaidia egefe) e da Na: ida: be medomusa: , sadoga sia: dalu ilegei. Na: ida: be amola ea dadi gagui wa: i, ilia da Filisidini fi moilai bai bagade Gibidonega doagala: loba, Ba: iasia da Na: ida: be medole legei.
Baaṣa ọmọ Ahijah ti ilé Isakari sì dìtẹ̀ sí i, Baaṣa sì kọlù ú ní Gibetoni, ìlú àwọn ará Filistini, nígbà tí Nadabu àti gbogbo Israẹli dó ti Gibetoni.
28 Amo hou da Yuda hina bagade A: isa ea ouligibi ode osodayale amoga ba: i. Amaiba: le, Ba: iasia da Na: ida: be bagia Yuda hina bagade hamoi.
Baaṣa sì pa Nadabu ní ọdún kẹta Asa ọba Juda, ó sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
29 Ha amogalawane, e da muni Yelouboua: me ea sosogo fi medole lelegelalu. Hina Gode da Ea hawa: hamosu balofede dunu Ahaidia (Siailou moilai fi dunu) amo ea lafidili sia: i defele, Yelouboua: me ea sosogo fi dunu huluanedafa da medole legei dagoi ba: i.
Ó sì ṣe, bí ó sì ti bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ ọba ó pa gbogbo ilé Jeroboamu, kò sì ku ẹnìkan tí ń mí fún Jeroboamu, ṣùgbọ́n ó run gbogbo wọn, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa, tí ó sọ nípa ọwọ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ Ahijah ará Ṣilo.
30 Amo hou doaga: i ea bai da Yelouboua: me da Isala: ili Hina Gode ougima: ne, wadela: le bagade hamoi, amola Isala: ili fi wadela: le hamoma: ne oule asi.
Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí Jeroboamu ti ṣẹ̀ àti tí ó mú Israẹli ṣẹ̀, àti nítorí tí ó ti mú Olúwa Ọlọ́run Israẹli bínú.
31 Na: ida: be ea hamoi huluane da “Isala: ili hina bagade ilia Hamonanusu Meloa” amo ganodini dedene legei.
Ní ti ìyókù ìṣe Nadabu àti gbogbo ohun tí ó ṣe, a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli?
32 Yuda hina bagade A: isa amola Isala: ili hina bagade Ba: iasia ela da elawa ouligisu eso amoga gebewane gegenanusu.
Ogun sì wà láàrín Asa àti Baaṣa ọba Israẹli ní gbogbo ọjọ́ wọn.
33 Yuda hina bagade A: isa ea ouligibi ode osodayale ganodini, Ba: iasia (Ahaidia egefe) da Isala: ili ilia hina bagade hamoi. E da Desa amo ganodini esala, ode 24agoane ouligilalu.
Ní ọdún kẹta Asa ọba Juda, Baaṣa ọmọ Ahijah sì jẹ ọba lórí gbogbo Israẹli ní Tirsa, ó sì jẹ ọba ní ọdún mẹ́rìnlélógún.
34 E da hina bagade Yelouboua: me ea hidadea hamoi defele, Hina Godema wadela: le hamonanu, amola Isala: ili fi wadela: le hamoma: ne oule asi.
Ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, ó sì rìn ní ọ̀nà Jeroboamu àti nínú ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀, èyí tí ó ti mú Israẹli ṣẹ̀.

< 1 Hina 15 >