< 1 Hina 14 >

1 Amogalu, hina bagade Yelouboua: me egefe Abaidia da olo madelai.
Ní àkókò náà Abijah ọmọ Jeroboamu sì ṣàìsàn,
2 Yelouboua: me da ea udama amane sia: i, “Dunu eno ilia da di mae dawa: digima: ne, dia da: i afadenene amola Siailou moilaiga masa. Amogai balofede dunu Ahaidia da esala. E da musa: na da Isala: ili ouligisu hamomu sia: i.
Jeroboamu sì wí fún aya rẹ̀ pé, “Lọ, sì pa ara rẹ dà, kí wọn kí ó má ba à mọ̀ ọ́n ní aya Jeroboamu. Nígbà náà ni kí o lọ sí Ṣilo. Ahijah wòlíì wà níbẹ̀; ẹni tí ó sọ fún mi pé, èmi yóò jẹ ọba lórí àwọn ènìyàn yìí.
3 Di agi ga: gi nabuane amola falaua fofaga: i eno amola agime hano di amo igili imunusa: gaguli masa. Ema amane adole ba: ma, ‘Ania mano oloi da esaloma: bela: ?’ Amasea, e da ania mano ea hou dima olelemu.”
Mú ìṣù àkàrà mẹ́wàá pẹ̀lú rẹ̀, àti àkàrà wẹ́wẹ́ àti ìgò oyin, kí o sì lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀. Òun yóò sì sọ fún ọ ohun tí yóò ṣẹlẹ̀ sí ọmọkùnrin náà.”
4 Amaiba: le, e da Ahaidia ea diasu Siailou moilaiga dialoba, amoga asi. Ahaidia da da: i hamoiba: le, ea si da dofoi dagoi.
Bẹ́ẹ̀ ni aya Jeroboamu sì ṣe bí ó ti wí, ó sì lọ sí ilé Ahijah ní Ṣilo. Ahijah kò sì ríran; ojú rẹ̀ ti fọ́ nítorí ogbó rẹ̀.
5 Yelouboua: me ea uda da ema ea mano oloi hou adole ba: la mana, e dawa: i galu. Bai Hina Gode da ema adoi galu. Amola Hina Gode da Ahaidia ea sia: amo sia: ma: ne olelei. Yelouboua: me ea uda da doaga: le, e da uda enoyale dawa: ma: ne afadenei.
Ṣùgbọ́n Olúwa ti sọ fún Ahijah pé, “Kíyèsi i, aya Jeroboamu ń bọ̀ wá béèrè nípa ọmọ rẹ̀ lọ́wọ́ rẹ, nítorí tí ó ṣàìsàn, báyìí báyìí ni kí ìwọ kí ó wí fún un. Nígbà tí ó bá dé, yóò ṣe ara rẹ̀ bí ẹlòmíràn.”
6 Be Ahaidia da e logo ga: su golili mabe nababeba: le, e amane sia: i, “Misa! Na dawa: , di da Yelouboua: me ea uda. Di da abuliba: le uda enoyale dawa: ma: ne, dia da: i afadenebela: ? Na da di da: i dioma: ne sia: mu gala.
Bẹ́ẹ̀ ni ó sì rí, nígbà tí Ahijah sì gbọ́ ìró ẹsẹ̀ rẹ̀ ní ẹnu-ọ̀nà, ó sì wí pé, “Wọlé wá, aya Jeroboamu. Kí ló dé tí ìwọ fi ṣe ara rẹ bí ẹlòmíràn? A ti fi iṣẹ́ búburú rán mi sí ọ.
7 Di asili, Yelouboua: mema amane sia: ma, ‘Isala: ili Hina Gode da dima amane sia: sa, Na da Isala: ili dunu fi amo ganodini di ilegele, di Na Isala: ili fi dunu ouligima: ne ilegei.
Lọ, sọ fún Jeroboamu pé báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, ‘Èmi sì gbé ọ ga láti inú àwọn ènìyàn, mo sì fi ọ́ jẹ olórí lórí Israẹli ènìyàn mi.
8 Na da ouligisu hou amo Da: ibidi ea fifi manebe ilima fadegale, dima i. Da: ibidi da Na hawa: hamosu maedafa fisili, Na hamoma: ne sia: i amola Na hanai amo huluane defele hamoi. Be di da amane hame hamoi.
Mo fa ìjọba náà ya kúrò ní ilé Dafidi, mo sì fi fún ọ ṣùgbọ́n, ìwọ kò dàbí Dafidi ìránṣẹ́ mi, tí ó pa àṣẹ mi mọ́, tí ó sì tọ̀ mí lẹ́yìn tọkàntọkàn rẹ̀, láti ṣe kìkì èyí tí ó tọ́ ní ojú mi.
9 Musa: Isala: ili ouligisu dunu ilia wadela: le hamosu. Be dia wadela: i hou da ilia wadela: i hou baligi dagoi. Di da Nama baligi fa: le amola Na ougima: ne, ogogole ‘gode’ ilima sia: ne gadomusa: , ifa, gele amola gula amoga hahamosu.
Ìwọ sì ti ṣe búburú ju gbogbo àwọn tí ó ti wà ṣáájú rẹ lọ. Ìwọ sì ti ṣe àwọn ọlọ́run mìíràn fún ara rẹ, àwọn òrìṣà tí a gbẹ́; o sì ti mú mi bínú, o sì ti gbé mi sọ sí ẹ̀yìn rẹ.
10 Amaiba: le, Na da dia sosogo fi huluane gugunufinisimu. Na da digaga dunu, asigilai amola goi, amo huluane fane lelegemu. Na da amane hamobeba: le, dia sosogo fi da hamedafa ba: mu. Ilia da iga gasa: le fasi agoai ba: mu.
“‘Nítorí èyí, Èmi yóò mú ibi wá sí ilé Jeroboamu. Èmi yóò ké gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin kúrò lọ́dọ̀ Jeroboamu, àti ọmọ ọ̀dọ̀ àti òmìnira ní Israẹli. Èmi yóò mú ilé Jeroboamu kúrò bí ènìyàn ti ń kó ìgbẹ́ kúrò, títí gbogbo rẹ̀ yóò fi tán.
11 Dia sosogo fi dunu afae da moilai ganodini bogosea, ea bogoi da: i hodo da wa: mega mai dagoi ba: mu. Amola sogega oda bogosea, buhibaga mai dagoi ba: mu. Na, Hina Gode, da sia: i dagoi.”
Ajá yóò jẹ ẹni Jeroboamu tí ó bá kú ní ìlú, àti ẹni tí ó bá kú ní igbó ni àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run yóò jẹ. Olúwa ti sọ ọ́!’
12 Amola, Ahaidia da Yelouboua: me iduama eno amane sia: i, “Be di, dia diasuga masa! Dia moilaiga doaga: le dasea, dia mano da bogomu.
“Ní ti ìwọ, padà lọ ilé, nígbà tí o bá sì fi ẹsẹ̀ rẹ tẹ ìlú, ọmọ náà yóò kú.
13 Isala: ili fi dunu huluane ilia da eha didigia: lalu, uli dogonesimu. Yelouboua: me ea sosogo fi amoga da e fawane noga: ledafa uli dogonesi ba: mu. Bai ema fawane, Isala: ili Hina Gode da nodosa.
Gbogbo Israẹli yóò sì ṣọ̀fọ̀ fún un, wọn yóò sì sin ín. Òun nìkan ni a ó sì sin nínú ẹni tí ń ṣe ti Jeroboamu, nítorí lọ́dọ̀ rẹ̀ nìkan ni a ti rí ohun rere díẹ̀ sípa Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ní ilé Jeroboamu.
14 Hina Gode da Isala: ili fi ouligima: ne, hina bagade eno ilegemu. E da Yelouboua: me ea sosogo fi ouligisu hou dagolesimu.
“Olúwa yóò gbé ọba kan dìde fúnra rẹ̀ lórí Israẹli tí yóò ké ilé Jeroboamu kúrò. Ọjọ́ náà nìyìí! Kí ni? Àní nísinsin yìí.
15 Hina Gode da Isala: ili dunu fima dawa: ma: ne se dabe imunu. Isala: ili dunu fi da saga: amo hano ganodini dialebe amo foga fananebe agoai ba: mu. E da ifa bai duga: su agoane Isala: ili dunu duga: le ilia sogedafa (amo E da ilia aowalalima i) amoga fisili masa: ne, soge amo da Iufala: idisi Hano na: iyado, amoga afagogolesisimu. Bai ilia da Hina Gode ougima: ne, ogogosu uda ‘gode’ Asila liligi loboga hamoi.
Olúwa yóò kọlu Israẹli, yóò sì dàbí koríko ti ń mì nínú omi. Yóò sì fa Israẹli tu kúrò ní ilẹ̀ rere yìí, tí ó ti fi fún àwọn baba wọn, yóò sì fọ́n wọn ká kọjá odò Eufurate, nítorí wọ́n ti rú ìbínú Olúwa nípa ṣíṣe ère Aṣerah.
16 Hina Gode da Isala: ili fi fisiagamu. Bai Yelouboua: me da wadela: le hamoi amola Isala: ili dunu fi wadela: le hamoma: ne oule asi.”
Yóò sì kọ Israẹli sílẹ̀ nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí Jeroboamu ti ṣẹ̀ àti tí ó mú Israẹli ṣẹ̀.”
17 Yelouboua: me idua da Desa moilai bai bagadega buhagi. E da ea moilaiga golili daloba, ea mano da bogoi.
Nígbà náà ni aya Jeroboamu sì dìde, ó sì lọ, ó sì lọ sí Tirsa. Bí ó sì ti fi ẹsẹ̀ tẹ ìloro ilé, ọmọdé náà sì kú.
18 Isala: ili dunu da, Hina Gode Ea hawa: hamosu balofede dunu Ahaidia ea lafidili sia: i defele, eha didigia: lalu, uli dogone sali.
Wọ́n sì sin ín, gbogbo Israẹli sì ṣọ̀fọ̀ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti wí láti ẹnu ìránṣẹ́ rẹ̀, Ahijah wòlíì.
19 Hina bagade Yelouboua: me ea hamoi hou (ea gegesu amola ea ouligisu hou) amo huluane da ‘Isala: ili fi hina bagade ilia Hamonanu Meloa’ amo ganodini dedene legei.
Ìyókù ìṣe Jeroboamu, bí ó ti jagun, àti bí ó ti jẹ ọba, ni a kọ sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Israẹli.
20 Yelouboua: me da Isala: ili dunu fi ouligilaloba, ode22 agoane gidigi. E da bogole, uli dogonesibiba: le, eagofe Na: ida: be da e bagia hina bagade hou lai.
Jeroboamu sì jẹ ọba fún ọdún méjìlélógún, ó sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀. Nadabu ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
21 Soloumane ea mano Lihouboua: me da lalelegele, ode 41 agoane esalu, Yuda soge fi ilia hina bagade hamoi. Amola, e da Yelusaleme moilai bai bagade (amo moilai fawane, Hina Gode da Isala: ili moilai huluane amoga Ema nodone sia: ne gadoma: ne ilegei) amo ganodini esala, ode 17 agoane Yuda fi ouligilalu. Lihouboua: me ea eme da Na: ima (A: mone fi uda).
Rehoboamu ọmọ Solomoni sì jẹ ọba ní Juda. Ó jẹ́ ẹni ọdún mọ́kànlélógún nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ sí ní jẹ ọba, ó sì jẹ ọba ní ọdún mọ́kànlélógún ní Jerusalẹmu, ìlú tí Olúwa ti yàn nínú gbogbo ẹ̀yà Israẹli láti fi orúkọ rẹ̀ síbẹ̀. Orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Naama, ará Ammoni.
22 Yuda fi dunu da Hina Godema wadela: le hamoi, amola E ougima: ne wadela: i hou amo da ilia aowalalia wadela: i hou hamosu, amo bagade baligi.
Juda sì ṣe búburú níwájú Olúwa nípa ẹ̀ṣẹ̀ wọn tí wọ́n ti dá, wọ́n sì mú u jowú ju gbogbo èyí tí baba wọn ti ṣe lọ.
23 Ilia da ogogole ‘gode’ma nodone sia: ne gadomusa: sogebi hahamoi. Ilia da agolaga amola ifa ougiha, amogai uda ogogole ‘gode’ Asila agoaila hahamoi amola igi golasu ifa duni bugi agoaila gagui.
Wọ́n sì tún kọ́ ibi gíga fún ara wọn, àti ère òkúta àti òpó Aṣerah lórí gbogbo òkè gíga, àti lábẹ́ gbogbo igi tútù.
24 Wadela: idafa hou da dunu amola uda ilia hina: da: i bidi lasu hou agoane wadela: i nodone sia: ne gadosu sogebi, amogai hamosu. Musa: Isala: ili dunu fi da Ga: ina: ne soge lamusa: gusuba: le ahoanoba, Hina Gode da Ga: ina: ne soge fi dunu gadili sefasi. Bai Ga: ina: ne dunu da gogosiasu wadela: i hou bagade hamonanebe ba: i. Amola fa: no, Lihouboua: me ea ouligibi galu, Yuda dunu amola da ilia wadela: i hou defele hamoi.
Àwọn tí wọn jẹ́ ọkùnrin alágbèrè ojúbọ òrìṣà wà ní ilẹ̀ náà, àwọn ènìyàn náà sì ṣe gẹ́gẹ́ bí gbogbo ohun ìríra àwọn orílẹ̀-èdè tí Olúwa ti lé jáde kúrò níwájú àwọn ọmọ Israẹli.
25 Ode biyale, Lihouboua: me ea ouligibi ganodini, Idibidi hina bagade Sisia: ge da Yelusaleme doagala: i.
Ó sì ṣe ní ọdún karùn-ún Rehoboamu, Ṣiṣaki ọba Ejibiti kọlu Jerusalẹmu.
26 E da noga: idafa liligi Debolo diasu amola hina bagade diasu amo ganodini diafulu, amola Soloumane ea gouliga hamoi da: igene ga: su, amo huluane lale, gagaguli asi.
Ó sì kó ìṣúra ilé Olúwa lọ àti ìṣúra ilé ọba. Gbogbo rẹ̀ ni ó kó lọ, pẹ̀lú asà wúrà tí Solomoni ti ṣe.
27 Amo bu ga: musa: , hina bagade Lihouboua: me da da: igene ga: su ‘balasega’ hahamonanu, eagene ouligisu dunu amo da hina bagade ea diasu ganodini dasu logo ga: su, amo sosodo aligisu, ilima ilia ouligima: ne, iasi.
Rehoboamu ọba sì ṣe asà idẹ ní ipò wọn, ó sì fi wọ́n sí ọwọ́ olórí àwọn olùṣọ́ tí ń ṣọ́ ìlẹ̀kùn ilé ọba.
28 Eso huluane, hina bagade da Debolo diasuga heda: loba, sosodo ouligisu dunu da amo da: igene ga: su gaguli heda: su, amalu bu manoba ilia da sosodo ouligisu sesei amo ganodini ligisisu.
Nígbàkígbà tí ọba bá sì lọ sí ilé Olúwa, wọ́n á rù wọ́n, wọ́n á sì mú wọn padà sínú yàrá olùṣọ́.
29 Hou huluane amo hina bagade Lihouboua: me hamoi da “Yuda hina bagade ilia Hamonanu Meloa” amo ganodini dedene legei.
Ní ti ìyókù ìṣe Rehoboamu, àti gbogbo ohun tí ó ṣe, ǹjẹ́ a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda bí?
30 Amo esoga, Lihouboua: me ea oule fi amola Yelouboua: me ea oule fi ili da gegenanu.
Ogun sì wà láàrín Rehoboamu àti Jeroboamu ní ọjọ́ wọn gbogbo.
31 Lihouboua: me da bogoi, amola ilia ea bogoi da: i hodo da Da: ibidi ea Moilaiga hina bagade ilia dogonesisu sogebi amoga uli dogone sali. Eagofe Abaidia da e bagia, Yuda dunu hina bagade hamoi.
Rehoboamu sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀, a sì sin ín pẹ̀lú wọn ní ìlú Dafidi. Orúkọ ìyá rẹ̀ sì ni Naama; ará Ammoni. Abijah ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.

< 1 Hina 14 >