< 1 Hou Olelesu 23 >

1 Da: ibidi da da: idafa hamonoba, e da egefe Soloumane da Isala: ili fi ilia hina bagade hamoi.
Nígbà tí Dafidi sì dàgbà, tí ó sì di arúgbó, ó sì fi Solomoni ọmọ rẹ̀ jẹ ọba lórí Israẹli.
2 Hina bagade Da: ibidi da Isala: ili fi ouligisu dunu amola gobele salasu dunu amola Lifai fi dunu huluane gilisi.
Ó sì kó gbogbo àgbàgbà Israẹli jọ, àti gẹ́gẹ́ bí àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi.
3 E da Lifai fi dunumusu amo da ode 30 agoane lalelegele esalu, amola ode 30 baligi, amo idimusa: ilia dio dedei. Ili idi da 38,000 agoane ba: i.
Àwọn ọmọ Lefi láti ọgbọ̀n ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ ni wọ́n kà àpapọ̀ iye àwọn ọkùnrin wọn sì jẹ́ ẹgbàá mọ́kàndínlógún.
4 Da: ibidi da ilima hawa: hamosu agoane ilelegei. Dunu 24,000 agoane da Debolo Diasu ouligima: ne ilelegei. Dunu 6,000 agoane da dawa: musa: dedene legesu ouligima: ne amola sia: ga gegesu fofada: su ouligima: ne ilelegei. Dunu 4,000 agoane da sosodo aligisu ouligima: ne ilelegei. Dunu 4,000 agoane da gesami hea: sa dusu liligi amo Da: ibidi ea i, amoga Hina Godema nodoma: ne ilelegei.
Dafidi sì wí pe, ní ti èyí, ẹgbàá méjìlá ni kí wọn jẹ́ alábojútó iṣẹ́ ilé fún Olúwa àti ẹgbẹ̀rún mẹ́fà ni kí ó ṣe olórí àti onídàájọ́.
5
Ẹgbàajì ni kí ó jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà àti ẹgbàajì ni kí o sì jẹ́ ẹni ti yóò máa yin Olúwa pẹ̀lú ohun èlò orin, mo ti ṣe èyí fún ìdí pàtàkì yìí.
6 Da: ibidi da gilisisu udiana hamoma: ne, Lifai fi dunu momogi. Amo gilisisu udiana da Gesione sosogo, Gouha: de sosogo amola Milalai sosogo.
Dafidi sì pín àwọn ọmọ Lefi sí ẹgbẹgbẹ́ láàrín àwọn ọmọ Lefi: Gerṣoni, Kohati àti Merari.
7 Gesione ea mano aduna da La: ida: ne amola Simiai.
Àwọn tí ó jẹ́ ọmọ Gerṣoni: Laadani àti Ṣimei.
8 La: ida: ne ea mano udiana da Yihaiele, Sida: me amola Youele.
Àwọn ọmọ Laadani Jehieli ẹni àkọ́kọ́, Setamu àti Joẹli, mẹ́ta ní gbogbo wọn.
9 Simiai ea mano udiana da Siloumidi, Ha: isiele amola Ha: ila: ne. (Ilia da La: ida: ne egaga fi ilima fada: i dunu esafulu)
Àwọn ọmọ Ṣimei: Ṣelomiti, Hasieli àti Harani mẹ́ta ní gbogbo wọn. Àwọn wọ̀nyí sì ni olórí àwọn ìdílé Laadani.
10 Simiai ea mano biyaduale da Ya: iha: de (magobo mano), Saina, Yeuse amola Bilaia da (ufi mano). Yeuese amola Bilaia elagaga fi da bagahameba: le, ela gilisili sosogo afae fawane idi.
Àti ọmọ Ṣimei: Jahati, Sina, Jeuṣi àti Beriah. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Ṣimei mẹ́rin ni gbogbo wọn.
Jahati sì ni alákọ́kọ́ Sinah sì ni ẹlẹ́ẹ̀kejì, ṣùgbọ́n Jeuṣi àti Beriah kò ní àwọn ọmọ púpọ̀; bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ka ara wọn sí ìdílé kan pẹ̀lú ìfilé lọ́wọ́ kan.
12 Gouha: de ea mano biyaduale da A: mala: me, Aisiha, Hibalone amola Asaiele.
Àwọn ọmọ Kohati: Amramu, Isari, Hebroni àti Usieli mẹ́rin ni gbogbo wọn.
13 Ea magobo dunu mano da A: mala: me. A: mala: me, egefela da Elane amola Mousese. (Elane amola egaga fi, ilia hawa: hamosu da agoane ilegei. Ilia da Hina Godema nodone sia: ne gadomusa: hadigi liligi amo ouligimu, Godema nodoma: ne gabusiga: manoma gobele salimu, Ea hawa: hamomu, amola Isala: ili dunuma Hina Gode Ea Dioba: le hahawane dogolegele hou imunu, amo huluane hamoma: ne ilegei dagoi.
Àwọn ọmọ Amramu. Aaroni àti Mose. A sì ya Aaroni sọ́tọ̀ òun àti àwọn ọmọ rẹ̀ títí láéláé, láti kọjú sí ohun mímọ́ jùlọ, láti fi rú ẹbọ sísun níwájú Olúwa, láti máa ṣe òjíṣẹ́ níwájú rẹ̀ àti láti kéde ìbùkún ní orúkọ rẹ̀ títí láéláé.
14 Be Gode Ea hawa: hamosu dunu Mousesegefela, da Lifai fi amo ganodini idi.)
Àwọn ọmọ Mose ènìyàn Ọlọ́run ni wọ́n kà gẹ́gẹ́ bí apá kan ẹ̀yà Lefi.
15 Mousese egefela da Gesiome amola Elia: isa.
Àwọn ọmọ Mose: Gerṣomu àti Elieseri.
16 Gesiome ea magobo mano da Sibiuele.
Àwọn ọmọ Gerṣomu: Ṣubaeli sì ni alákọ́kọ́.
17 Elia: isa da dunu mano afadafa galu. Ea dio da Liha: baia. Be Liha: baia egaga fi dunu da bagohame galu.
Àwọn ọmọ Elieseri: Rehabiah sì ni ẹni àkọ́kọ́. Elieseri kò sì tún ní ọmọ mìíràn, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Rehabiah wọ́n sì pọ̀ níye.
18 Gouha: de magobo bagia dunu mano da Aisiha. Aisiha egefe da Siloumidi. E da ea sosogo fi ilima fada: i galu.
Àwọn ọmọ Isari: Ṣelomiti sì ni ẹni àkọ́kọ́.
19 Gouha: de egefe Aisiha amo bagia da Hibalone. Hibalone egefelali da Yelaia, A:malaia, Yaha: isiele amola Yega: mia: ne.
Àwọn ọmọ Hebroni: Jeriah sì ni ẹni àkọ́kọ́, Amariah sì ni ẹni ẹ̀ẹ̀kejì, Jahasieli sì ni ẹ̀ẹ̀kẹ́ta àti Jekameamu ẹ̀ẹ̀kẹrin.
20 Gouha: de egefe ufi da Asaiele. Asaiele egefela da Maiga amola Yisaia: i.
Àwọn ọmọ Usieli: Mika ni àkọ́kọ́ àti Iṣiah ẹ̀ẹ̀kejì.
21 Milalai egefela da Malai amola Miusiai. Malai egefela da Elia: isa amola Gisia.
Àwọn ọmọ Merari: Mahili àti Muṣi. Àwọn ọmọ Mahili: Eleasari àti Kiṣi.
22 Elia: isa da dunu mano hamedene, bogoi. E da uda manomusu galu. Ea uda manoni da ilia elafi (Gisia egefelali) ilima fi.
Eleasari sì kú pẹ̀lú àìní àwọn ọmọkùnrin: Ó ní ọmọbìnrin nìkan. Àwọn ọmọ ẹ̀gbọ́n, àwọn ọmọ Kiṣi, sì fẹ́ wọn.
23 Milalai egefe magobo bagia amo Miusiai egefelali da Malai, Ide amola Yelimode.
Àwọn ọmọ Muṣi: Mahili, Ederi àti Jerimoti mẹ́ta ni gbogbo wọn.
24 Amo dunu huluane da Lifai egaga fifi misi. Ili huluane da ilia dio amola ilia sosogo fi defele, dedene legei ba: i. Lifai egaga fi dunu amo da ode 20 amola baligi, ilia huluane afae afae da Hina Gode Ea Debolo Diasu ganodini hawa: hamonanu.
Àwọn wọ̀nyí sì ni ọmọ Lefi bí ìdílé wọn. Olórí ìdílé gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti fi orúkọ sílẹ̀ lábẹ́ orúkọ wọn, ó sì kà wọn ní ẹyọ kọ̀ọ̀kan, wí pé, àwọn òṣìṣẹ́ tí ó jẹ́ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ tí ń ṣiṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa.
25 Da: ibidi da amane sia: i, “Isala: ili fi ilia Hina Gode da Ea fi ilima olofosu i dagoi. Amola Hisu da Yelusaleme ganodini eso huluane esalalalumu.
Nítorí pé Dafidi ti sọ pé, “Níwọ̀n ìgbà tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli, ti fi ìsinmi fún àwọn ènìyàn tí ó kù tí sì ń gbé Jerusalẹmu títí láéláé,
26 Amaiba: le, Lifai fi dunu ilia da Hina Gode Ea Hadigi Abula Diasu amola liligi Godema nodone sia: ne gadomusa: hamoi, amo gaguli masunu hawa: hamosu da hame gala.”
àwọn ọmọ Lefi kò sì tún ru àgọ́ tàbí ọ̀kankan lára àwọn ohun èlò tí wọ́n ń lò níbi ìsìn rẹ̀.”
27 Da: ibidi ea dagomusa: gini hamoma: ne sia: beba: le, Lifai dunu huluane da ilia lalelegei ode 20 amoga doaga: loba, hawa: hamoma: ne dedene legei.
Gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ ìkẹyìn Dafidi sí, àwọn ọmọ Lefi, wọ́n sì kà wọ́n, bẹ̀rẹ̀ láti orí àwọn ọmọ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ.
28 - Ilia da amo hawa: hamoma: ne ilegei: - (a) Elane egaga fi gobele salasu dunu, ilia Debolo Diasu ganodini Godema nodone sia: ne gadosu, amo fidima: ne ilegei. (b) Debolo gagoi amola sesei huluane, amola hadigi Godema nodone sia: ne gadomusa: liligi huluane amo noga: le ouligima: ne ilegei. (c) Ilia da Godema iasu liligi huluane ouligima: ne ilegei. Amo da agi, falaua, Yisidi hame sali belawagi, amola falaua amola olife susuligi gilisi iasu. (d) Ilia da Debolo gobele salasu liligi huluane dioi defei amola sedade defei, amo ba: ma: ne ilegei. (e) Ilia da hahabe, amola daeya, amola adi esoga Isala: ili dunu da Sa: bade gobele salasu amola Oubi Gaheabologa Lolo Nasu gobele salasu hamoi, Hina Godema nodone sia: ne gadosu hou, mae fisili hamonanoma: ne ilegei dagoi. (f) Ilia da Hina Gode Ea Abula Diasu amola Debolo Diasu noga: le ouligima: ne ilegei. Amola ilia da ilia fi dunu amo Elane egaga fi gobele salasu dunu, amo ilia Debolo ganodini Godema nodone sia: ne gadosu hou fidima: ne, Lifai fi da ilegei dagoi ba: i.
Iṣẹ́ àwọn ọmọ Lefi ni láti ran àwọn ọmọ Aaroni lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ wọn fún ti ilé Olúwa: láti wà lábẹ́ ìkáwọ́ agbára ìlú, àti ẹ̀gbẹ́ ilé, àti ìwẹ̀nùmọ́ ti gbogbo ohun ìyàsọ́tọ̀ àti ṣíṣe ohun tí í ṣe iṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa.
Wọ́n sì wà ní ìkáwọ́ àkàrà tí wọ́n mú jáde láti orí tábìlì, àti ìyẹ̀fun fún ẹbọ, àti àkàrà aláìwú, àti fún púpọ̀ àti èyí tí a pòpọ̀, àti gbogbo onírúurú ìwọ̀n àti wíwọ̀n àti òsùwọ̀n.
Wọ́n sì gbọdọ̀ dúró ní gbogbo òwúrọ̀ láti dúpẹ́ àti láti yin Olúwa. Wọ́n sì gbọdọ̀ ṣe irú kan náà ní àṣálẹ́.
Àti láti rú ẹbọ sísun fún Olúwa ní ọjọ́ ìsinmi àti ní àsìkò oṣù tuntun àti ní àjọ̀dún tí a yàn. Wọ́n gbọdọ̀ sìn níwájú Olúwa lójoojúmọ́ ní iye tó yẹ àti ní ọ̀nà tí a ti pàṣẹ fún wọn.
Bẹ́ẹ̀ ni nígbà náà, àwọn ọmọ Lefi gbé ìgbékalẹ̀ jáde fún ìpàdé àgọ́, fún Ibi Mímọ́ àti, lábẹ́ àwọn arákùnrin àwọn ọmọ Aaroni fún ìsìn ilé Olúwa.

< 1 Hou Olelesu 23 >