< 1 Hou Olelesu 18 >

1 Amogalu fa: no, hina bagade Da: ibidi da bu Filisidini dunu doagala: le, ili hasali. Amalalu, Filisidini dunu ilia Isala: ili sogega ouligimusa: dawa: i da ne gumi ba: i.
Ní àkókò kan, Dafidi kọlu àwọn ará Filistini, ó sì ṣẹ́gun wọn. Ó sì mú Gati àti àwọn ìletò agbègbè rẹ̀ kúrò lábẹ́ ìdarí àwọn ará Filistini.
2 Amalalu, Da: ibidi da Moua: be dunu hasali. Amaiba: le, e da Moua: be fi dunu ilima ouligisu hamoi, amola ilia da ema su (‘da: gisi’) iasu.
Dafidi borí àwọn ará Moabu, wọ́n sì di ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀, wọ́n sì mú owó òde wá.
3 Amalalu, e da Ha: da: disa (E da Silia soge fonobahadi amo Souba amoga hina bagade galu) amo hasali. Ha: da: disa da soge Iufala: idisi Hano gusudili ouligilalu. Be mafua dunu da lelebeba: le, e da amoga ouligisu fisi. E da amo sogega ouligisu hou bu lamusa: ahoanoba, Da: ibidi da e doagala: i.
Síbẹ̀, Dafidi sì kọlu Hadadeseri ọba Soba ní Hamati, bí ó ti ń lọ láti fi ìdí ìjọba rẹ̀ múlẹ̀ létí odò Eufurate.
4 Da: ibidi da sa: liode 1,000 agoane, dadi gagui dunu hosi da: iya fila heda: i 7,000 agoane amola emoga ahoasu dadi gagui dunu 20,000 agoane gagulaligi. E da hosi idi, amo da sa: liode 100 agoane hiougima: ne defele gala, amo gagulaligi. E da hosi eno huluane mae masa: ne, ilia emo dina: fe dadamunisisi.
Dafidi fi agbára gba ẹgbẹ̀rún kẹ̀kẹ́ rẹ̀, ẹ̀ẹ́dẹ́gbàárin agun-kẹ̀kẹ́ àti ogún ẹgbẹ̀rún ológun ilẹ̀. Ó sì já gbogbo ọgọ́rùn-ún iṣan ẹsẹ̀ àwọn kẹ̀kẹ́-ẹṣin náà.
5 Silia fi dunu Dama: sagase moilai bai bagadega esalu da hina bagade Ha: da: disa fuli gala: ma: ne dadi gagui wa: i asunasi. Be Da: ibidi da amo wa: i doagala: le, 22,000 dunu fane lelegei.
Nígbà ti àwọn ará Siria ti Damasku wá láti ran Hadadeseri ọba Soba lọ́wọ́, Dafidi lu ẹgbẹ̀rún méjìlélógún wọn bọ lẹ̀.
6 Amalalu, e da ilia soge ganodini ha wa: i fisu diasu gilisisu gaguli gagai. E da ili ouligibiba: le, ilia da ema su (‘da: gisi’) iasu. Hina Gode da Da: ibidi fidibiba: le, e da habi ahoanoba, hasalasu hou fawane ba: su.
Ó sì fi àwọn ọ̀wọ́ ọmọ-ogun rẹ sínú ìjọba Siria ti Damasku, àwọn ará Siria sì ń sìn ní abẹ́ rẹ̀, wọ́n sì mú owó ìṣákọ́lẹ̀ wá. Olúwa sì ń fún Dafidi ní ìṣẹ́gun ní ibi gbogbo tí ó bá lọ.
7 Da: ibidi da gouliga hamoi da: igene ga: su amo Ha: da: disa ea eagene ouligisu dunu ilia gaguli ahoasu, amo samogene, Yelusaleme moilai bai bagadega gaguli asi.
Dafidi mú àpáta wúrà tí àwọn ìjòyè Hadadeseri gbé, ó sì gbé wọn wá sí Jerusalẹmu.
8 Amola e da ‘balase’ bagadedafa Dibaha: de amola Gune (amo moilai bai bagade aduna Ha: da: disa ea ouligisu) amoga samogei. (Fa: no, Soloumane da Debolo Diasu ofodo sugi, duni bugi amola Debolo hawa: hamosu liligi, amo balasega hamoi)
Láti Tibhati àti Kuni, àwọn ìlú Hadadeseri, Dafidi kó ọ̀pọ̀lọpọ̀ idẹ tí Solomoni lò láti fi ṣe okùn idẹ, àwọn òpó àti oríṣìí ohun èlò idẹ.
9 Ha: ima: de soge hina bagade ea dio amo Doui, e da Da: ibidi da Ha: da: disa ea dadi gagui wa: i hasali, amo sia: nabi.
Nígbà tí Tou ọba Hamati gbọ́ pé Dafidi ti borí gbogbo ọmọ-ogun Hadadeseri ọba Soba.
10 Amaiba: le, e da egefe Youla: me amo Da: ibidima nodone sia: ma: ne asunasi. Bai Da: ibidi da Ha: da: disa hasali, amola Doui da eso bagohame Ha: da: disama gegenanusu. Youla: me da gouli amola silifa amola balase amoga hamoi liligi Da: ibidima gaguli asili, ema hahawane i.
Ó rán ọmọ rẹ̀ Hadoramu sí ọba Dafidi láti kí i àti láti lọ bá a yọ̀ lórí ìṣẹ́gun rẹ̀ nínú ogun lórí Hadadeseri, tí ó wà lójú ogun pẹ̀lú Tou. Hadoramu mú oríṣìíríṣìí ohun èlò ti wúrà àti fàdákà àti idẹ wá.
11 Hina bagade Da: ibidi da amo liligi amola eno silifa amola gouli e da fifi asi eno amo hasali (Idome, Moua: be, A:mone, Filisidini amola A: malege) amoga samogei, amo gilisili, Hina Godema nodone sia: ne gadoma: ne ilegei. Amola liligi amo e da Ha: da: disa amoma samogei, mogili agoane ilegei.
Ọba Dafidi ya ohun èlò wọ́n yí sí mímọ́ fún Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe pẹ̀lú fàdákà àti wúrà tí ó ti mú láti gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí: Edomu àti Moabu, ará Ammoni àti àwọn ará Filistini àti Amaleki.
12 Abisia: i (ea ame da Selouaia) da Deme Fago ganodini amo Idome dunu hasali dagoi. E da Idome dunu 18,000 agoane fane legei.
Abiṣai ọmọ Seruiah lu ẹgbàá mẹ́sàn ará Edomu bolẹ̀ ní àfonífojì Iyọ̀.
13 E da Idome soge ganodini, dadi gagui ha wa: i fisisu diasu gilisisu gaguli gagai, amola e da Idome dunu ouligisu. Hina Gode da Da: ibidi fidibiba: le, e da habidili ahoanoba, hasalasisu hou fawane ba: i.
Ó fi ẹgbẹ́ ogun sí Edomu, gbogbo àwọn ará Edomu sì ń sìn ní abẹ́ Dafidi. Olúwa fún Dafidi ní ìṣẹ́gun ní gbogbo ibí tí ó bá lọ.
14 Da: ibidi da Isala: ili soge huluanedafa ouligisu. E da ouligibiba: le, ea fi dunu da moloidafa hou fawane ba: i.
Dafidi jẹ ọba lórí gbogbo Israẹli, ó sì ṣe òdodo àti ohun tí ó yẹ fún gbogbo àwọn ènìyàn rẹ̀.
15 Abisia: i ola Youa: be, e da dadi gagui wa: i ilia ouligisu galu. Yihosiafa: de (Ahailade egefe) da sia: dedei ouligisu galu.
Joabu ọmọ Seruiah jẹ́ olórí ẹgbẹ́ ọmọ-ogun; Jehoṣafati ọmọ Ahiludi jẹ́ akọ̀wé ìrántí;
16 Sa: idoge (Ahaidabe egefe) amola Ahimelege (Abaia: da egefe) da gobele salasu dunu esalu. Hina bagade fi sia: dedesu dunu da Sila: ia galu.
Sadoku ọmọ Ahitubu àti Abimeleki ọmọ Abiatari jẹ́ àwọn àlùfáà; Ṣafṣa jẹ́ akọ̀wé;
17 Bina: ia (Yihoiada egefe) da Da: ibidi ea da: igene sosodo aligisu dunuma ouligisu galu. Amola Da: ibidi ea egefelali da ea hawa: hamosu dunu mimogo hamoi.
Benaiah ọmọ Jehoiada jẹ́ olórí àwọn Kereti àti Peleti; àwọn ọmọ Dafidi sì ni àwọn olóyè oníṣẹ́ ní ọ̀dọ̀ ọba.

< 1 Hou Olelesu 18 >