< Leviticus 27 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé.
Hina Gode da Mousesema amane hamoma: ne sia: i,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Bí ẹnìkan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ pàtàkì láti ya ènìyàn kan sọ́tọ̀ fún Olúwa nípa sísan iye tí ó tó,
“Isala: ili dunu ilima amane sia: ma,” Nowa da Godema imunusa: , dunu ilegesea, e da amo dunu bu samogene lamu da defea. Be e da amo dunu ea dabe defele imunu.
3 kí iye owó ọkùnrin láti ọmọ ogún ọdún sí ọgọ́ta ọdún jẹ́ àádọ́ta òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà, gẹ́gẹ́ bí òsùwọ̀n ṣékélì ti ibi mímọ́ Olúwa.
Dabe lamu defei da hagudu dedei, asigilai dunu amo da ode20 asili ode60 doaga: i, ea dabe lamu defei da silifa fage50agoane asigilai uda ea dabe lamu defei da silifa fage30 agoane goi amo da ode5 asili20 doaga: i, ea dabe lamu defei da silifa fage20agoane uda mano ea dabe lamu defei da silifa fage10 agoane dunu mano dudubu (ode oasili5) ea dabe lamu defei da silifa fage5agoane uda mano dudubu ea dabe lamu defei da silifa fage3 agoane asigilai dunu amo da ode60 baligi, ea dabe lamu defei da silifa fage15agoane asigilai uda amo daode60baligi amo ea dabe lamu defei da silifa fage10agoane.
4 Bí ẹni náà bá jẹ obìnrin, kí iye owó rẹ̀ jẹ́ ọgbọ̀n òsùwọ̀n ṣékélì.
5 Bí ẹni náà bá jẹ́ ọmọ ọdún márùn-ún sí ogún ọdún, kí iye owó rẹ̀ jẹ́ ogún ṣékélì fún ọkùnrin àti òsùwọ̀n ṣékélì mẹ́wàá fún obìnrin.
6 Bí ẹni náà bá jẹ́ ọmọ oṣù kan sí ọdún márùn-ún, kí iye owó rẹ̀ jẹ́ òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà márùn-ún fún ọkùnrin àti òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà mẹ́ta fún obìnrin.
7 Bí ẹni náà bá jẹ́ ọmọ ọgọ́ta ọdún àti jù bẹ́ẹ̀ lọ, kí iye owó rẹ̀ jẹ́ òsùwọ̀n ṣékélì mẹ́ẹ̀ẹ́dógún fún ọkùnrin àti òsùwọ̀n ṣékélì mẹ́wàá fún obìnrin.
8 Bí ẹnìkan tí ó jẹ́ ẹ̀jẹ́ bá tálákà púpọ̀ dé bi pé kò lè san iye owó náà, kí a mú ẹni náà wá síwájú àlùfáà, àlùfáà yóò sì dá iye owó tí ó lè san lé e gẹ́gẹ́ bí agbára ẹni náà tí ó jẹ́ ẹ̀jẹ́.
Be dunu da eno dunu ilegei amola hame gaguiba: le, bu defei amo defele lamu hamedei ba: sea, e da ea ilegei dunu o uda, gobele salasu dunu ema oule masa: ne sia: ma. Amasea, gobele salasu dunu da ilegei hamoi dunu ea gagui defele, dabe lamu defei haguduga ilegemu.
9 “‘Bí ẹ̀jẹ́ tí ó jẹ́ bá jẹ́ ẹranko èyí tí ó jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà gẹ́gẹ́ bí ọrẹ fún Olúwa, irú ẹran bẹ́ẹ̀ tí a bá fi fún Olúwa di mímọ́.
10 Ẹni tí ó jẹ́ ẹ̀jẹ́ náà kò gbọdọ̀ pàrọ̀ ẹran mìíràn, yálà kí ó pàrọ̀ èyí tí ó dára sí èyí tí kò dára tàbí èyí tí kò dára sí èyí tí ó dára. Bí ó bá ṣe bẹ́ẹ̀ ti Olúwa ni ẹranko méjèèjì.
Be dunu da Hina Godema imunusa: , ohe noga: i ilegesea, e da amo ohe afadenene eno ohe imunu da hamedei. Bai Hina Godema ilegei iasu da sema gala. E da ohe afadenene, eno imunusa: dawa: sea, amo ohe aduna da Hina Gode Ea:
11 Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ ní ti ẹranko àìmọ́ tí a fi tọrẹ: èyí tí kò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà bí i ọrẹ fún Olúwa. Kí ọkùnrin náà mú ọrẹ náà lọ fún àlùfáà.
Be ilegei liligi amo da ledo galebe ohe (Hina Gode da agoai liligi hame laha) amo galea, dunu da amo ohe gobele salasu dunuma gaguli masunu.
12 Kí àlùfáà díye lé e, gẹ́gẹ́ bí ó ti dára tàbí bí ó ti bàjẹ́ sí. Iye owó náà ni kí ó jẹ́.
Gobele salasu dunu da amo ohe ea hou defele lamu defei ilegemu. Amo lamu defei afadenemu da hamedei galebe.
13 Bí ẹni náà bá fẹ́ rà á padà, ó gbọdọ̀ san iye owó rẹ̀ àti ìdá ogún iye owó náà láfikún.
Iasu dunu da amo ohe bu bidi lamusa: dawa: sea, e da bidi lamu defei amola20% eno amola bidi lamusa: imunu.
14 “‘Bí ẹnikẹ́ni bá ya ilẹ̀ rẹ̀ sí mímọ́ fún Olúwa: kí àlùfáà kó sọ iye tí yóò san gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ náà ti dára tàbí bàjẹ́ sí, iye owó náà ni kí ó jẹ́.
Nowa dunu da ea diasu Hina Godema imunusa: ilegesea, gobele salasu dunu da amo diasu ea hou defele, bidi lamu defele ilegemu. Amo bidi lamu defei afadenemu da hamedei.
15 Bí ẹni tí ó yá ilé náà sí mímọ́ bá fẹ́ rà á padà. Jẹ́ kí ó fi ìdámárùn-ún owó ìdíyelé rẹ̀ kún ún, yóò si jẹ́ tirẹ̀.
Be dunu amo diasu imunusa: ilegei da amo diasu bu bidi lamusa: dawa: sea, e da diasu ea bidi lamu defei amola20% eno amola amoga bu bidi lamu.
16 “‘Bí ẹnìkan bá sì ya ara ilẹ̀ ìdílé rẹ̀ sí mímọ́ fún Olúwa. Iye tí ó bá jẹ́ ni kí wọ́n ṣètò gẹ́gẹ́ bí iye èso tí a ó fi gbìn ín. Àádọ́ta ṣékélì fàdákà fún òsùwọ̀n homeri irúgbìn barle.
Dunu da Hina Godema imunusa: ea soge ilegesea, amo ea bidi lamu defei da fage hawa: amo sogea bugima: ne ea defei agoane ba: mu. Idi da bali hawa: 20gilougala: me afae afae da silifa fage nabuane amoga lamu.
17 Bí ó ba ṣe pé ní ọdún ìdásílẹ̀ ni ó ya ilẹ̀ náà sí mímọ́. Iye owó tí wọn sọtẹ́lẹ̀ náà ni kí o san.
Be Bu Sagosu Ode doaga: sea, amolalu e da hedolo Hina Godema imunusa: ilegesea, amo ea bu lamusa: defei da huluanedafa.
18 Bí ó bá ya ilẹ̀ náà sí mímọ́ lẹ́yìn ọdún ìdásílẹ̀ kí àlùfáà sọ iye owó tí yóò san fún ọdún tókù kí ọdún ìdásílẹ̀ mìíràn tó pé iye owó tí ó gbọdọ̀ jẹ yóò dínkù.
Be e da fa: nowane ilegesea, gobele salasu dunu da ode asili, Bu Sagosu Ode doaga: mu, amo ode idilalu ea bu bidi lamu defei ilegemu.
19 Bí ẹni tí ó ya ilẹ̀ sí mímọ́ bá fẹ́ rà á padà, kí ó san iye owó náà pẹ̀lú àfikún ìdámárùn-ún. Ilẹ̀ náà yóò sì di tirẹ̀.
Dunu amo da musa: amo soge Hina Godema ilegei, e da bu bidi lamusa: dawa: sea, e da amo ea bidi lamu defei amola eno20% amoga bu bidi lamu.
20 Bí kò bá ra ilẹ̀ náà padà tàbí bí ó bá tà á fún ẹlòmíràn kò le è ri rà padà mọ́.
Be amo dunu da amo soge Hina Godema bu mae bidi lale, eno dunuma bidi lasea, e da amo soge bu hamedafa bidi lamu - sema gala.
21 Bí a bá fi ilẹ̀ náà sílẹ̀ ní ọdún ìdásílẹ̀ yóò di mímọ́ gẹ́gẹ́ bí ilẹ̀ tí a fi fún Olúwa. Yóò sì di ohun ìní àlùfáà.
Bu Sagosu Ode eno doaga: sea, amo soge da Hina Gode Ea: liligi, eso huluane enoga mae bidi lama: ne, hamoi dagoi ba: mu. Gobele salasu dunu ilia da amo soge gagumu.
22 “‘Bí ẹnikẹ́ni bá ya ilẹ̀ tí ó ti rà tí kì í ṣe ilẹ̀ ìdílé rẹ̀ sí mímọ́ fún Olúwa.
Dunu da soge bidi lale, Hina Godema amo soge imunusa: ilegesea,
23 Kí àlùfáà sọ iye tí ó tọ títí di ọdún ìdásílẹ̀. Kí ọkùnrin náà sì san iye owó náà ní ọjọ́ náà gẹ́gẹ́ bí ohun mímọ́ sí Olúwa.
gobele salasu dunu da ode asili Bu Sagosu Ode amoga doaga: mu, amo ode idilalu, amo soge bidi lamu defei ilegemu. Amasea, amo dunu da defei amo defele amo esodafaga hedolo imunu. Bidi i amo da Hina Gode Ea:
24 Ní ọdún ìdásílẹ̀ ilẹ̀ náà yóò padà di ti ẹni tí ó ni í, lọ́wọ́ ẹni tí a ti rà á.
Bu Sagosu Ode amoga, soge da ea musa: eda o egaga fi ilima bu sinidigili ima: mu.
25 Gbogbo iye owó wọ̀nyí gbọdọ̀ wà ní ìbámu pẹ̀lú ṣékélì ibi mímọ́, ogún gera.
Bidi lamu defei da Isala: ili fi bidi lasu sema ilegei defele hamoi dagoi ba: mu.
26 “‘Kò sí ẹni tí ó gbọdọ̀ ya gbogbo àkọ́bí ẹran sọ́tọ̀. Èyí jẹ́ ti Olúwa nípasẹ̀ òfin àkọ́bí: yálà akọ màlúù ni tàbí àgùntàn, ti Olúwa ni.
Isala: ili sema amo ganodini, magobo lalelegei huluane da Hina Gode Ea: Amaiba: le, dilia da magobo amo hahawane udigili iasu hamomu da hamedei. Bai amo da Hina Gode Ea: liligi. Bulamagau mano o sibi mano o goudi mano da Hina Gode Ea:
27 Bí ó bá jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ẹran tí kò mọ́, nígbà náà ni kí ó rà á padà gẹ́gẹ́ bí ìdíyelé rẹ̀, kí ó sì fi ìdámárùn-ún lé e, tàbí bí a kò bá rà á padà kí ẹ tà á gẹ́gẹ́ bí ìdíyelé rẹ̀.
Be ledo gala ohe amo da ilegei hame ohe ea bidi lasu defei defele amola eno20% amola amoga bu bidi lamu da defea. Be ea eda da bu hame bidi lasea, gobele salasu dunu da eno dunuma ea lamu defei ilegei amoga bidi lamu da defea.
28 “‘Ohun tí a bá yà sí mímọ́ pátápátá láti ọwọ́ ẹnikẹ́ni sí Olúwa tàbí ẹranko tàbí ilẹ̀ tí ó jogún, òun kò gbọdọ̀ tà á kí ó rà á padà. Gbogbo ohun ìyàsọ́tọ̀ bẹ́ẹ̀ di mímọ́ jùlọ fún Olúwa.
Be liligi o dunu o ohe o soge da bu hame lamusa: Hina Godema ilegesea, amo bu samogemu da hamedei. Bai amo liligi da eso huluane Hina Gode Ea:
29 “‘Ẹni tí ẹ bá ti yà sọ́tọ̀ fún pípa, ẹnikẹ́ni kò gbọdọ̀ rà á padà, pípa ni kí ẹ pa á.
Dunu amola da medole legemusa: Hina Godema ilegei, amo bu lamu da hamedei. Amo da medole legemu fawane.
30 “‘Gbogbo ìdámẹ́wàá ilẹ̀ náà yálà tí èso ilẹ̀ ni, tàbí tí èso igi, ti Olúwa ni. Mímọ́ ni fún Olúwa.
Sogega heda: i ha: i manu huluane, (gala: ine amola ifa fage) amo nabuane momogili, afae da Hina Gode Ea:
31 Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ ra ìdámẹ́wàá nǹkan rẹ̀ padà, o gbọdọ̀ fi márùn-ún kún un.
Nowa da Hina Gode Ea liligi bu lamusa: dawa: sea, e da amo ea bidi lamu defei defele amola eno20% amoga bu lamu.
32 Gbogbo ìdámẹ́wàá àgbò àti ẹran ọ̀sìn, àní ìdámẹ́wàá ẹran tó bá kọjá lábẹ́ ọ̀pá darandaran kí ó jẹ́ mímọ́ fún Olúwa.
Lai gebo ilia idi nabuane ganodini, afae da Hina Gode Ea:
33 Ènìyàn kò gbọdọ̀ wádìí bóyá ó dára tàbí kò dára, kò sì gbọdọ̀ pààrọ̀ rẹ̀. Bí ó bá pààrọ̀ rẹ̀: àti èyí tí ó pààrọ̀ àti èyí tí ó fi pààrọ̀ ni kí ó jẹ́ mímọ́. Wọn kò gbọdọ̀ rà á padà.’”
Amo ohe ea eda da amo nabuane idi amo ganodini, wadela: i ohe fawane Hina Godema imunu da sema bagade. Amola ohe noga: i amo da Hina Godema ilegei, amo afadenene eno imunu da sema bagade. Amai hamosea., amo ohe aduna da Hina Gode Ea: ba: mu, amola ela bu bidi lamu da hamedei.
34 Àwọn àṣẹ wọ̀nyí ni Olúwa pa fún Mose fún àwọn ọmọ Israẹli ní orí òkè Sinai.
Hina Gode da amo hamoma: ne sia: i huluane Sainai Goumia Mousesema i. E da Isala: ili fi dunu ilima alofele ima: ne, Mousesema sia: si. Sia: Ama Dagoi

< Leviticus 27 >