< Joshua 19 >

1 Kèké kejì jáde fún ẹ̀yà Simeoni, ní agbo ilé, ní agbo ilé. Ìní wọn sì wà ní àárín ilẹ̀ Juda.
A hmulung pabae te Simeon ham neh Simeon ca rhoek, anih koca rhoek ham, amah cako tarhing ah a yueh pah vaengah amih kah rho loh Judah ca rhoek kah rho khui ah kap.
2 Lára ìpín wọn ní: Beerṣeba (tàbí Ṣeba), Molada,
Amih kah rho khuiah Beersheba, Sheba neh Moladah,
3 Hasari-Ṣuali, Bala, Esemu,
Hazarshual, Balah neh Ezem,
4 Eltoladi, Betuli, Horma,
Eltolad, Bethul neh Hormah,
5 Siklagi, Beti-Markaboti, Hasari Susa,
Ziklag, Bethmarkaboth neh Hazarsusah,
6 Beti-Lebaoti àti Ṣarueli, ìlú wọn jẹ́ mẹ́tàlá àti ìletò wọn.
Bethlebaoth, Sharuhen khopuei hlai thum neh a vangca rhoek,
7 Aini, Rimoni, Eteri àti Aṣani, ìlú wọn jẹ́ mẹ́rin àti ìletò wọn,
Ayin Rimmon, Ether, Ashan khopuei pali neh a vangca rhoek,
8 àti gbogbo àwọn agbègbè ìlú wọ̀nyí títí dé Baalati-Beeri (Rama ní gúúsù). Èyí ni ilẹ̀ ìní ẹ̀yà àwọn ọmọ Simeoni, agbo ilé, ní agbo ilé.
Khopuei rhoek kaepvai vangca boeih Baaltahbeer tuithim Ramath duela Simeon ca rhoek amih, amah cako tarhing ah amih koca kah rho la om.
9 A mú ogún ìní àwọn ọmọ Simeoni láti ìpín Juda, nítorí ìpín Juda pọ̀ ju èyí tí wọ́n nílò lọ. Báyìí ni àwọn ọmọ Simeoni gba ìní wọn ní àárín ilẹ̀ Juda.
Judah ca rhoek kah khoyo he muep a om dongah Simeon ca rhoek rho he Judah ca rhoek kah khoyo dongah a kap pah. Te dongah amih kah rho khuikah te Simeon koca rhoek loh a pang uh.
10 Kèké kẹta jáde fún Sebuluni, ní agbo ilé ní agbo ilé ààlà ìní wọn sì lọ títí dé Saridi.
A pathum ah Zebulun ca rhoek ham te amah cako tarhing ah hmulung a naan pah. Amih rho kah khorhi he Sarid duela cet.
11 Ó sì lọ sí ìwọ̀-oòrùn ní Marala, ó sì dé Dabbeṣeti, ó sì lọ títí dé odo ní ẹ̀bá Jokneamu.
Te dongah amih khorhi he khotlak la luei. Dabbaseth ah Maralah te a doo tih Jokneam dan kah soklong te a doo thil.
12 Ó sì yípadà sí ìlà-oòrùn láti Saridi sí ìhà ìlà-oòrùn dé ilẹ̀ Kisiloti-Tabori, ó sì lọ sí Daberati, ó sì gòkè lọ sí Jafia.
Te phoeiah khothoeng Sarid lamkah khocuk la, Kislothtabor khorhi la mael tih Daberath la a pawk phoeiah Japhia la luei.
13 Nígbà náà ní o lọ sí ìhà ìlà-oòrùn lọ sí Gati-Heferi àti Eti-Kaṣini, ó sì jáde ní Rimoni, ó sì yí sí ìhà Nea.
Te lamkah te khocuk, khothoeng la, Gathhepher la, Ethkazin la kat tih Neah la aka hooi Rimmon la pawk.
14 Ní ibẹ̀, ààlà sì yíká ní ìhà àríwá lọ sí Hnatoni ó sì pín ní àfonífojì Ifita-Eli.
Hannathon tlangpuei ah khorhi loh a hil tih a hmoi te kolrhawk ah om.
15 Lára wọn ni Katati, Nahalali, Ṣimroni, Idala àti Bẹtilẹhẹmu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlá àti ìletò wọn.
Kattath, Nahalal, Shimron, Idalah, Bethlehem, kho hlai nit neh amih vangca rhoek,
16 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní Sebuluni, ní agbo ilé agbo ilé.
Te khopuei neh a vangca rhoek he Zebulun koca rhoek neh a hui a ko kah rho la om.
17 Kèké kẹrin jáde fún Isakari, agbo ilé ní agbo ilé.
Hmulung a pali te Issakhar ham, Issakhar koca rhoek kah a hui a ko tarhing la a naan.
18 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí: Jesreeli, Kesuloti, Ṣunemu,
Te dongah Jezreel Kesulloth neh Shunem,
19 Hafraimu, Ṣihoni, Anaharati,
Hapharaim, Shion neh Anaharath,
20 Rabiti, Kiṣioni, Ebesi,
Rabibith, Kishion neh Ebez,
21 Remeti, Eni-Gannimu, Eni-Hada àti Beti-Pasesi.
Remeth, Engannim, Enhadah neh Bethpazzez te amih kah khorhi la om.
22 Ààlà náà sì dé Tabori, Ṣahasuma, àti Beti-Ṣemeṣi, ó sì pin ní Jordani. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mẹ́rìndínlógún àti ìletò wọn.
Te phoeiah khorhi loh Tabor neh Shahazumah, Shahazumah neh Bethshemesh te a doo tih Jordan kah khopuei hlai rhuk neh a vangca rhoek te amih kah rhi hmoi la om.
23 Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní ẹ̀yà Isakari, ní agbo ilé agbo ilé.
He khopuei vangca rhoek Issakhar ca rhoek, amih koca rhoek neh a hui a ko tarhing kah rho la om.
24 Kèké karùn-ún jáde fún ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
Hmulung a panga te Asher ca rhoek, amih koca neh a hui a ko tarhing la a naan pah.
25 Lára ilẹ̀ wọn ni èyí: Helikati, Hali, Beteni, Akṣafu,
Te dongah Helkath, Hali, Beten neh Akshaph,
26 Allameleki, Amadi, àti Miṣali. Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ààlà náà dé Karmeli àti Ṣihori-Libinati.
Allammelek, Amad, Mishal neh khotlak Karmel, Shihorlibnath te a doo.
27 Nígbà náà ni o yí sí ìhà ìlà-oòrùn Beti-Dagoni, dé Sebuluni àti àfonífojì Ifita-Eli, ó sì lọ sí àríwá sí Beti-Emeki àti Neieli, ó sì kọjá lọ sí Kabulu ní apá òsì.
Te phoeiah khocuk Bethdagon la mael tih Zebulun neh tlangpuei kolrhawk, Bethemek neh Neiel te a doo phoeiah banvoei Kabuul la pawk.
28 Ó sì lọ sí Abdoni, Rehobu, Hammoni àti Kana títí dé Sidoni ńlá.
Ebron neh Rehob, Hammon, Kanah, Sidon puei due,
29 Ààlà náà sì tẹ̀ sí ìhà Rama, ó sì lọ sí ìlú olódi Tire, ó sì yà sí Hosa, ó sì jáde ní Òkun Ńlá ní ilẹ̀ Aksibu,
khorhi te Ramah neh khopuei hmuencak Tyre la bal. Te phoeiah Hosah khorhi ah aka mael te cet phai tih Akhzib rhi ah a hmoi te pawk.
30 Uma, Afeki àti Rehobu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlélógún àti ìletò wọn.
Ummah, Aphek, Rehob khopuei pakul panit neh vangca rhoek he amih kah khorhi ana om.
31 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
Hekah khopuei rhoek neh vangca rhoek he Asher ca rhoek, amih koca a hui a ko kah rho la om.
32 Ìpín kẹfà jáde fún Naftali, agbo ilé ní agbo ilé,
Hmulung a parhuk te Naphtali ca rhoek ham neh Naphtali ca rhoek kah a hui a ko tarhing ah a naan pah.
33 ààlà wọn lọ láti Helefi àti igi ńlá ní Saananimu nímù; kọjá lọ sí Adami Nekebu àti Jabneeli dé Lakkumu, ó sì pín ní Jordani.
Te dongah amih kah khorhi tah Heleph, Zaanannim thingnu neh Adami, Jabneel lamloh Lakkuum la thoeng tih a hmoi te Jordan om.
34 Ààlà náà gba ìhà ìwọ̀-oòrùn lọ sí Asnoti-Tabori ó sì jáde ní Hukoki. Ó sì dé Sebuluni, ní ìhà gúúsù Aṣeri ní ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Juda ní Jordani ní ìhà ìlà-oòrùn.
Khorhi he khotlak Aznothtabor lam khaw yong tih Hukkuk la pawk. Te phoeiah tuithim Zebulun te a doo tih khotlak kah Asher neh khocuk Jordan, Judah te a pha.
35 Àwọn ìlú olódi sì Siddimu, Seri, Hamati, Rakàti, Kinnereti,
Te dongah khopuei hmuencak rhoek Ziddim Zer, Khammath, Rakkath neh Kinnereth,
36 Adama, Rama Hasori,
Adamah, Ramah neh Hazor,
37 Kedeṣi, Edrei, Eni-Aṣọri,
Kedesh, Edrei, Enhazor,
38 Ironi, Migdali-Eli, Horemu, Beti-Anati àti Beti-Ṣemeṣi. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mọ́kàndínlógún àti ìletò wọn.
Iron, Migdalel, Horem, Bethanath, Bethshemesh khopuei hlai ko neh amih kah vangca rhoek,
39 Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Naftali, ní agbo ilé sí agbo ilé.
tekah khopuei rhoek neh vangca rhoek te Naphtali ca rhoek, amih koca neh a hui a ko kah rho la om.
40 Ìbò kéje jáde fún ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé ní agbo ilé.
Dan ca rhoek, amih koca ham a hui a ko tarhing la hmulung a parhih te a naan pah.
41 Ilẹ̀ ìní wọn nìwọ̀nyí: Sora, Eṣtaoli, Iri-Ṣemesi,
Te vaengah amih kah khorhi rho la Zorah, Eshtaol neh Shemesh khopuei,
42 Ṣaalabini, Aijaloni, Itila,
Shaalabin, Aijalon neh Ithlah,
43 Eloni, Timna, Ekroni,
Elon, Timnah, Ekron,
44 Elteke, Gibetoni, Baalati,
Eltekeh, Gibbethon, Baalath,
45 Jehudu, Bene-Beraki, Gati-Rimoni,
Jehud, Beneberak, Gathrimmon,
46 Me Jakoni àti Rakkoni, pẹ̀lú ilẹ̀ tí ó kọjú sí Joppa.
Me Jarkon, Rakkon neh Joppa imdan rhi te a om pah.
47 (Ṣùgbọ́n àwọn ará Dani ní ìṣòro láti gba ilẹ̀ ìní wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gòkè lọ, wọ́n sì kọlu Leṣemu, wọ́n sì gbà á, wọ́n sì fi idà kọlù ú, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀. Wọ́n sì ń gbé ní Leṣemu, wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ní Dani orúkọ baba ńlá wọn).
Dan ca rhoek kah khorhi he te lamkah hang khuen coeng dae Dan ca rhoek te cet uh tih Leshem te a tloek thil uh. Anih te a buem uh tih cunghang ha neh a ngawn uh tih a huul uh. A khuiah kho a sak vaengah tah a napa Dan kah ming voel la Leshem Dan la a sui uh.
48 Àwọn ìlú wọ́n yí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé agbo ilé.
Te khopuei rhoek neh a vangca rhoek te Dan ca rhoek, anih koca neh a hui a ko kah rho la om.
49 Nígbà tí wọ́n ti parí pínpín ilẹ̀ náà ní ìpín ti olúkúlùkù, àwọn ará Israẹli fún Joṣua ọmọ Nuni ní ìní ní àárín wọn,
Khohmuen te a rhilung neh phaeng ham a khah uh vaengah Israel ca rhoek amamih khui kah loh Nun capa Joshua te rho a paek uh.
50 bí Olúwa ti pàṣẹ, wọ́n fún un ni ìlú tí ó béèrè fún, Timnati Serah ní ìlú òkè Efraimu. Ó sì kọ́ ìlú náà, ó sì ń gbé ibẹ̀.
BOEIPA ol vanbangla a bih khopuei, Ephraim tlang ah Timnathkhehres te anih a paek uh tih a khuiah kho a thong tih kho a sak.
51 Wọ̀nyí ni àwọn ilẹ̀ tí Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti àwọn olórí ẹ̀yà agbo ilé Israẹli fi ìbò pín ní Ṣilo ní iwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Báyìí ni wọ́n parí pínpín ilẹ̀ náà.
Tekah rho rhoek te khosoih Eleazar, Nun capa Joshua, Israel ca rhoek kah koca rhoek khuiah a napa rhoek kah a lu aka om rhoek loh Shiloh kah tingtunnah dap thohka BOEIPA mikhmuh ah hmulung la a phaeng uh tih khohmuen a tael te a khah uh.

< Joshua 19 >