< Jeremiah 2 >

1 Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá wí pé:
LEUM GOD El fahk nu sik
2 “Lọ kí o sì kéde sí etí Jerusalẹmu pé: “Báyìí ni Olúwa wí, “‘Èmi rántí ìṣeun ìgbà èwe rẹ, ìfẹ́ ìgbéyàwó rẹ àti nígbà tí ìwọ tẹ̀lé mi nínú ijù, nínú ìyàngbẹ ilẹ̀.
in sulkakin mwe fahkak se inge nu sin mwet nukewa in Jerusalem. “Nga esam lupan pwaye ac oaru lom nu sik ke kom srakna mutan fusr, Fuka lupan lungse lom nu sik ke kut tufahna payukyak. Kom tuh fahsrna tukuk in acn mwesis, Sie acn ma soenna oasr ma yok we.
3 Israẹli jẹ́ mímọ́ sí Olúwa, àkọ́kọ́ èso ìkórè rẹ̀, gbogbo ẹnikẹ́ni tí ó jẹ run ni a ó dá lẹ́bi, ibi yóò sì wá sí orí wọn,’” bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí.
Israel, kom tuh sriyukla in ma na luk; Kom sie ma mutal nu sik mukena. Nga fah supu mwe keok ac mwe ongoiya Nu faclos nukewa su akkeokye kom. Nga, LEUM GOD, pa fahk ma inge.”
4 Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin ìdílé Jakọbu àti gbogbo ẹ̀yin ará ilé Israẹli.
Porongo mwe fahkak lun LEUM GOD, kowos fwilin tulik natul Jacob ac sruf lun Israel.
5 Báyìí ni Olúwa wí: “Irú àìṣedéédéé wo ni baba yín rí lọ́wọ́ mi, tí wọ́n fi jìnnà sí mi? Wọ́n tẹ̀lé àwọn òrìṣà asán, àwọn fúnra wọn sì di asán.
LEUM GOD El fahk: “Ma koluk fuka papa matu tomowos ah konauk in nga? Efu ku elos forla likiyu? Elos alu nu ke ma sruloala ma wangin sripa, Oru elos ekla pac mwet wangin sripa.
6 Wọn kò béèrè, ‘Níbo ni Olúwa wà, tí ó mú wa jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá, tí ó mú wa la aginjù já, tí ó mú wa la àárín pẹ̀tẹ́lẹ̀ àti ihò, ìyàngbẹ ilẹ̀ àti òkùnkùn biribiri, ilẹ̀ ibi tí ẹnikẹ́ni kò là kọjá, tí ẹnikẹ́ni kò sì tẹ̀dó sí?’
Elos tiana nunku keik, Nga ne molelosla liki acn Egypt Ac kololosme sasla yen mwesis; Sie acn turangang ac pukanten luf we, Sie acn pao ac facl in misa, Yen wangin mwet muta we Ac wangin pac mwet fufahsryesr we.
7 Èmi mú yín wá sí ilẹ̀ ọlọ́ràá láti máa jẹ èso ibẹ̀ àti ọrọ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ẹ̀yin wọ inú rẹ̀, ẹ sì bà á jẹ́, ẹ sì sọ ogún mi di ohun ìríra.
Nga usalosme nu in sie facl kasrup ac wo fohk we, Elos in insewowo ke kosrani we ac ke ma wo pac saya. A elos tuh akkolukyela facl sik; Elos akfohkfokyela facl se su nga sang nu selos.
8 Àwọn àlùfáà kò béèrè wí pé, ‘Níbo ni Olúwa wà?’ Àwọn tí ń ṣiṣẹ́ pẹ̀lú òfin kò si mọ̀ mí, àwọn olùṣọ́ sì ṣẹ̀ sí mi. Àwọn wòlíì sì ń sọtẹ́lẹ̀ nípa òrìṣà Baali, wọ́n sì ń tẹ̀lé àwọn òrìṣà asán.
Mwet tol elos tiana siyuk, ‘LEUM GOD El oasr oya?’ Elos su sasla ke ma sap elos tia eteyu. Mwet kol elos tuyak lainyu. Mwet palu kaskas ke inen Baal, Ac alu nu ke ma sruloala lusrongten.
9 “Nítorí náà, mo fi ẹ̀sùn kàn yín lẹ́ẹ̀kan sí i,” ni Olúwa wí. “Èmi ó sì fi ẹ̀sùn kan àwọn ọmọ ọwọ́ rẹ.
“Ouinge nga, LEUM GOD, fah akkalemye ma nga lain kowos kac. Nga fah tia tui in lain fwilin tulik nutuwos.
10 Rékọjá lọ sí erékùṣù àwọn ara Kittimu, kí ẹ sì wò ó, ránṣẹ́ lọ sí ìlú Kedari, kí ẹ sì kíyèsi gidigidi; kí ẹ wò bí irú nǹkan báyìí bá ń bẹ níbẹ̀?
Som nu layen roto, nu ke tuka Cyprus, Ac supwala sie mwet nu layen kutulap nu in facl Kedar. Kowos fah liye lah wangin kain inge nu sikyak meet.
11 Orílẹ̀-èdè kan ha á pa ọlọ́run rẹ̀ dà? (Síbẹ̀, wọ́n kì í ṣe iṣẹ́ ọlọ́run.) Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi ti pààrọ̀ Ọlọ́run ògo wọn fún àwọn ère tí kò níyì.
Wangin sie mutunfacl nu aolla god la uh, God inge finne tia god pwaye. A mwet luk uh tuh sisyula, God se su akwoyalos, Ac elos forla nu ke god ma tia ku in oru kutena ma nu selos.
12 Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì kí ẹ sì wárìrì pẹ̀lú ìbẹ̀rù ńlá,” ni Olúwa wí.
Ke ma inge nga sapkin yen engyeng uh in rarrarak ke mwe aksangeng, In fwefela ac oela,
13 “Àwọn ènìyàn mi ti dẹ́ṣẹ̀ méjì, wọ́n ti kọ̀ mí sílẹ̀, Èmi orísun omi ìyè, wọ́n sì ti ṣe àmù, àmù fífọ́ tí kò lè gba omi dúró.
Tuh mwet luk elos orala ma koluk luo: Elos forla likiyu, Nga su unon in kof loslos nu selos, Ac elos pukanak lufin kof — Lufin kof su wohn ac tia ku in sruokya kof.
14 Israẹli ha á jẹ́ ọmọ ọ̀dọ̀ ẹrú nípa ìbí? Kí ló ha a dé tí ó fi di ìkógun?
“Israel el tia sie mwet kohs; Tia osweyukla el nu ke moul in kohs. Na efu ku mwet lokoalok lal suk in sruokilya?
15 Àwọn kìnnìún ké ramúramù; wọ́n sì ń bú mọ́ wọn. Wọ́n ti fi ilẹ̀ rẹ̀ ṣòfò; ìlú rẹ̀ ti di jíjóná, ó sì ti di ìkọ̀sílẹ̀.
Elos kouyak nu sel oana pusren lion uh. Elos kunausla facl sel, oan mwesasla, Ac siti we musalla ac wanginla mwet muta we.
16 Bákan náà, àwọn ọkùnrin Memfisi àti Tafanesi wọ́n ti fa adé orí rẹ yọ.
Aok, mwet Memphis ac Tahpanhes Elos fukulya sri in ahlunsifal.
17 Ẹ̀yin kò ha a ti fa èyí sórí ara yín nípa kíkọ Olúwa Ọlọ́run sílẹ̀ nígbà tí ó tọ́ ọ lójú ọ̀nà?
Israel, kom na pa sifacna oru in upa nu sum! Kom sisyula, LEUM GOD lom, Ke nga tuh pwen kom inkanek uh.
18 Kí ló dé tí o ṣe wá lọ Ejibiti láti lọ mu omi ní Ṣihori? Kí ló dé tí o sì fi lọ sí Asiria láti lọ mú omi ni odò Eufurate náà?
Ya oasr ma ac wo nu sum kom fin som nu Egypt In nim kof ke Infacl Nile? Ya oasr ma ac wo nu sum kom fin som nu Assyria In nim kof ke Infacl Euphrates?
19 Iṣẹ́ búburú yín yóò fìyà jẹ yín ìpadàsẹ́yìn rẹ yóò sì bá ọ wí mọ̀ kí o sì rí i wí pé ibi àti ohun búburú yóò sì jẹ́ tìrẹ nígbà tí o ti kọ Olúwa Ọlọ́run sílẹ̀, ẹ kò sì ní ìbẹ̀rù fún mi,” ni Olúwa, Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
Ma koluk lom sifacna ac fah kai kom, Ac forla lom likiyu fah liskomla. Kom ac fah akilen lah sie ma na koluk ac mwen Pa in sisla LEUM GOD lom, Ac tila inse pwaye nu sik. Nga, LEUM GOD Fulatlana ac Kulana, pa fahk ma inge.”
20 “Nígbà àtijọ́, o ti fọ́ àjàgà rẹ sọnù, ìwọ sì já ìdè rẹ; ìwọ wí pé, ‘Èmi kì yóò sìn ọ́!’ Lóòtítọ́, lórí gbogbo òkè gíga ni àti lábẹ́ igi tí ó tànkálẹ̀ ni ìwọ dùbúlẹ̀ sí gẹ́gẹ́ bí panṣágà.
LEUM GOD Fulatlana El fahk, “Israel, kom nuna srunga na muta ye ku luk oemeet me. Kom tiana akosyu ku alu nu sik. Fin mangon eol nukewa, Ac ye sak folfol nukewa Kom tuh alu nu ke god eslap uh.
21 Èmi ti gbìn ọ́ gẹ́gẹ́ bí àjàrà ọ̀tọ̀, gẹ́gẹ́ bí ìṣúra ọlọ́lá. Báwo wá ni ìwọ ṣe yípadà sí mi di àjàrà búburú àti aláìmọ́?
Nga yukwikomi oana soko fain sacnsan Ke fita ma wo oemeet. Na liye ma kom ekla nu kac inge! Kom oana soko fain kolukla ac wanginla sripa.
22 Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé o wẹ ara rẹ pẹ̀lú sódà tí o sì lo ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọṣẹ síbẹ̀síbẹ̀ èérí ni ẹ̀ṣẹ̀ rẹ níwájú,” ni Olúwa Olódùmarè wí.
Kom finne oulkomla ke soap na ku Nga ac srakna liye tuhn fohkfok lun ma koluk lom.
23 “Báwo ni ìwọ ṣe wí pé, ‘Èmi kò ṣe aláìmọ́, Èmi kò sá à tẹ̀lé àwọn Baali’? Wo bí o ṣe hùwà ní àfonífojì; wo ohun tí o ṣe. Ìwọ jẹ́ abo ìbákasẹ tí ń sá síyìn-ín sọ́hùn-ún.
Efu ku kom ku in fahk mu kom tiana aktaekye monum, Ac fahk mu kom tiana wi alu nu sel Baal? Esam lupan ma koluk kom oru infahlfal uh; Ngetang liye ma kom orala inge. Kom oana soko camel mutan lemnak Ma yuwot yume sukok camel mukul,
24 Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó tí ń gbé aginjù tí ń fa ẹ̀fúùfù ìfẹ́ sí i mu rẹ, ta ni ó le è mú dúró ní àkókò rẹ̀? Kí gbogbo àwọn akọ ẹran tí o wá a kiri kì ó má ṣe dá ara wọn lágara, nítorí wọn yóò rí ní àkókò oṣù rẹ̀.
Sasang nu in yen turangang uh. In pacl el ouinge uh, su ac ku in kutongilya? Camel mukul ma lungse el uh fah tia enenu in sokol, Mweyen el pa ac sokolos.
25 Dá ẹsẹ̀ dúró láìwọ bàtà, àti ọ̀fun rẹ nínú òǹgbẹ. Ṣùgbọ́n ìwọ wí pé, ‘Asán ni! Èmi fẹ́ràn àwọn ọlọ́run àjèjì, àwọn ni èmi yóò tọ̀ lẹ́yìn.’
Israel, nimet aktotoye niom, Ku lela in paola kapinsrulyom Ke ukweyen god ngia. A kom fahk, ‘Mo! Nga tia ku in forla. Nga lungse god saya uh, ac nga fah ukwalos.’”
26 “Gẹ́gẹ́ bí a ṣe ń dójútì olè nígbà tí a bá mú u, bẹ́ẹ̀ náà ni ojú yóò ti ilé Israẹli— àwọn ọba àti àwọn ìjòyè wọn, àwọn àlùfáà àti wòlíì wọn pẹ̀lú.
LEUM GOD El fahk, “Oana ke sie mwet pisrapasr el ac mwekinla ke ac sruhu el, kowos mwet Israel nukewa ac fah mwekinla pac — tokosra, mwet fulat, mwet tol ac mwet palu lowos.
27 Wọ́n sọ fún igi pé, ‘Ìwọ ni baba mi,’ àti sí òkúta wí pé, ‘Ìwọ ni ó bí mi,’ wọ́n ti kọ ẹ̀yìn wọn sí mi, wọn kò kọ ojú sí mi síbẹ̀ nígbà tí wọ́n bá wà nínú ìṣòro, wọn yóò wí pé, ‘Wá kí o sì gbà wá!’
Kowos nukewa ac fah mwekinla — kowos su fahk mu sak soko pa papa tomowos ac eot se pa nina kiowos. Ma inge ac sikyak mweyen kowos forla likiyu ac tia nget nu sik. Tusruktu ke pacl se kowos ac sun ongoiya, na kowos ac siyuk nga in tuku ac molikowosla.
28 Níbo wá ni àwọn ọlọ́run tí ẹ ṣe fúnra yín ha a wà? Jẹ́ kí wọ́n wá kí wọ́n sì gbà yín nígbà tí ẹ bá wà nínú ìṣòro! Nítorí pé ẹ̀yin ní àwọn ọlọ́run púpọ̀, gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ni àwọn ìlú, ìwọ Juda.
“Pia god ma kowos sifacna taflela nu suwos uh? Pacl kowos ac sun ongoiya, lela elos in molikowosla, elos fin ku! Arulana pusla god lowos, oana pisen siti in acn Judah.
29 “Kí ló dé tí o ṣe wá ń fi ẹ̀sùn kàn mí? Gbogbo yín ni ó ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi,” ni Olúwa wí.
Mea kowos torkaskas kac uh? Efu kowos orekma koluk na lainyu?
30 “Nínú asán mo fìyà jẹ àwọn ènìyàn yín, wọn kò sì gba ìbáwí. Idà yín ti pa àwọn wòlíì yín run, gẹ́gẹ́ bí kìnnìún tí ń bú ramúramù.
Nga tuh kai kowos, tusruk wanginna sripa mweyen kowos tia lela nga in luti kowos. Kowos uniya mwet palu lowos, oana soko lion sulallal.
31 “Ẹ̀yin ìran yìí, ẹ kíyèsi ọ̀rọ̀ Olúwa: “Mo ha ti di aginjù sí Israẹli tàbí mo jẹ ilẹ̀ olókùnkùn biribiri? Èéṣe tí àwọn ènìyàn mi ṣe wí pé, ‘A ní àǹfààní láti máa rìn kiri; àwa kì yóò tọ̀ ọ́ wá mọ́?’
Mwet Israel, porongo ma nga fahk uh. Ya nga oana sie acn mwesis nu suwos, oana sie acn lohsr ac sensen? Na efu kowos ku fahk mu kowos ac oru oana lungse lowos, ac kowos ac tiana foloko nu yuruk?
32 Wúńdíá ha le gbàgbé ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀, tàbí ìyàwó ohun ọ̀ṣọ́ ìgbéyàwó rẹ̀? Síbẹ̀, àwọn ènìyàn mi ti gbàgbé mi ní ọjọ́ àìníye.
Ya sie mutan fusr ku in mulkunla mwe naweyuk lal, ku sie mutan akola in marut ku in mulkunla nuknuk in marut lal? Tia ku. Tusruktu nga tia ku in oakla pisen len mwet luk uh mulkinyula.
33 Ìwọ ti jẹ́ ọlọ́gbọ́n tó nípa ọ̀rọ̀ ìfẹ́! Àwọn obìnrin búburú yóò kẹ́kọ̀ọ́ nípa ọ̀nà rẹ.
Kom arulana etu in konauk mukul kom lungse orek pwar se. Finne mutan koluk se, el ku in lutlut sum.
34 Lórí aṣọ rẹ ni wọ́n bá ẹ̀jẹ̀ àwọn tálákà aláìṣẹ̀, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ìwọ kò ká wọn mọ́ níbi tí wọ́n ti ń rùn wọlé. Síbẹ̀ nínú gbogbo èyí
Nuknuk lom tuhnla ke srahn mwet sukasrup su wangin mwata, tia ke srahn mwet pisrapasr. “Tusruktu finne ma inge nukewa orek,
35 ìwọ sọ wí pé, ‘Èmi jẹ́ aláìṣẹ̀; kò sì bínú sí mi.’ Èmi yóò mú ìdájọ́ mi wá sórí rẹ nítorí pé ìwọ wí pé, ‘Èmi kò dẹ́ṣẹ̀.’
a kom srakna fahk mu, ‘Wangin mwetik! LEUM GOD El tiana kasrkusrak sik.’ Tusruktu nga, LEUM GOD, fah kai kom mweyen kom lafwekin lah kom orekma koluk.
36 Èéṣe tí ìwọ fi ń lọ káàkiri láti yí ọ̀nà rẹ padà? Ejibiti yóò dójútì ọ́ gẹ́gẹ́ bí i ti Asiria.
Efu ku arulana fisrasr sum in ikikil nunak lom? Kom ac toasrla sin Egypt, oana ke kom tuh toasrla sin Assyria.
37 Ìwọ yóò sì fi ibẹ̀ sílẹ̀ pẹ̀lú kíkáwọ́ rẹ lé orí rẹ, nítorí pé Olúwa ti kọ̀ àwọn tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé sílẹ̀, kì yóò sí ìrànlọ́wọ́ kankan fún ọ láti ọ̀dọ̀ wọn.
Kom ac fah forla liki Egypt, ac suwoli ke mwekin. Nga, LEUM GOD, siselosla su kom lulalfongi. Wangin kutena ma wo kom ac eis selos.”

< Jeremiah 2 >