< Isaiah 36 >
1 Ní ọdún kẹrìnlá ìjọba Hesekiah, Sennakeribu ọba Asiria kọlu gbogbo àwọn ìlú olódi ní ilẹ̀ Juda ó sì kó gbogbo wọn.
Ode 14 amo hina bagade Hesigaia ea Yuda fi ouligibiga, Sena: gelibi (Asilia hina bagade) da Yuda gagoi gagili sali moilai amoma doagala: le, suguli lai dagoi.
2 Lẹ́yìn náà, ọba Asiria rán olórí ogun rẹ̀ pẹ̀lú ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọmọ-ogun láti Lakiṣi sí ọba Hesekiah ní Jerusalẹmu. Nígbà tí ọ̀gágun náà dúró níbi ojúṣàn adágún ti apá òkè, ní ojú ọ̀nà sí pápá alágbàfọ̀,
Amalalu, e da ea bisilua ouligisu dunu, amo da dadi gagui dunu gilisisu amoma bisili, La: igisi moilai bai bagade fisili, Yelusalemega asili, hina bagade Hesigaia amoma e da bu gegesu fisili, Yelusaleme ema imunu, amo sia: ma: ne asunasi. Amo ouligisu dunu da asili, logo amoga abula hahamosu dunu da hawa: hamosu (amo da hano logo da gadodili hano wayabo amoga hano gaguli maha, amo gadenene), amo logoga esalu.
3 Ṣebna Eliakimu ọmọ Hilkiah alábojútó ààfin, Ṣebna akọ̀wé, àti Joah ọmọ Asafu akọ̀wé jáde lọ pàdé rẹ̀.
Yuda dunu udiana da ema misi. Ilia dio da Ilaiagime (Hiligaia egefe) amola Siebena (sia: dedesu dunu) amola Youa (A: isa: fe egefe).
4 Ọ̀gágun náà sọ fún wọn wí pé, “Ẹ sọ fún Hesekiah, “‘Èyí yìí ni ohun tí ọba ńlá, ọba Asiria sọ pé: Lórí i kí ni ìwọ gbé ìgbẹ́kẹ̀lé tìrẹ yìí lé?
Asilia bisilua ouligisu dunu da Hesigaia da Asilia hina bagadema abuliba: le hame beda: i, amo hou dawa: musa: hanai galu.
5 Ìwọ sọ wí pé ìwọ ní ète àti agbára ogun—ṣùgbọ́n ìwọ ń sọ ọ̀rọ̀ asán. Ta ni ìwọ gbẹ́kẹ̀lé tí ìwọ fi ṣọ̀tẹ̀ sí mi?
E amane sia: i, “Dilia da adi dawa: bela: ? Sia: fawane da gasa bagade dadi gagui gilisisu amola gegesu dawa: su hou amoga hasanasima: bela: ? Dilia da Asilia ilima odoga: sea, nowa da fidima: bela: ?
6 Wò ó nísinsin yìí, ìwọ gbẹ́kẹ̀lé Ejibiti ẹ̀rún igi ọ̀pá lásán tí í gún ni lọ́wọ́ tí í sì í dọ́gbẹ́ sí ni lára tí a bá gbára lé e! Bẹ́ẹ̀ ni Farao ọba Ejibiti sí àwọn tí ó bá gbẹ́kẹ̀lé e.
Dilia da Idibidi da dili fidimu dawa: lala. Be amo hou da dilia gasa hame saga: lale, galiamo hamomusa: dawa: su defele. Amo da fili, dia lobo somu. Idibidi hina bagade ea hou da agoaiwane gala. Nowa da ea fidisu hou dafawaneyale dawa: sea da se nabimu.”
7 Bí o bá sì sọ fún mi pé, “Àwa gbẹ́kẹ̀lé Olúwa Ọlọ́run wa,” kì í ṣe òun ni Hesekiah ti mú àwọn ibi gíga àti pẹpẹ rẹ̀ kúrò, tí ó sì wí fún Juda àti Jerusalẹmu pé, “Ẹ̀yin gbọdọ̀ sìn níwájú pẹpẹ yìí”?
Asilia ouligisu dunu da eno amane sia: i, “Dilia da dilia Hina Gode da dili fidima: ne dawa: bela: ? Hesigaia da Yuda dunu amola Yelusaleme dunu ilima ilia ‘oloda’ afae fawane amoga Godema sia: ne gadomusa: sia: beba: le, e da dilia Hina Gode Ea ‘oloda’ amola sia: ne gadosu liligi eno wadela: lesi dagoi.
8 “‘Ẹ wá nísinsin yìí, bá ọ̀gá mi pa ìmọ̀ pọ̀, ọba Asiria, èmi yóò fún ọ ní ẹgbẹ̀rún méjì ẹṣin bí ìwọ bá le è fi agẹṣin lé wọn lórí!
Na da na hina bagade ea dioba: le, dilima agoane hou hamomu. Dilia da dunu 2000 agoane, hosi fila heda: ma: ne defele esala amo hogole ba: sea, na da dilima hosi 2000 agoane ili fila heda: ma: ne imunu.
9 Báwo ni ẹ ṣe lè lé ẹyọ kan ṣoṣo padà nínú èyí tí ó kéré jù nínú àwọn balógun olúwa mi, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ gbẹ́kẹ̀lé Ejibiti fún kẹ̀kẹ́-ẹṣin àti àwọn ẹlẹ́ṣin?
Dilia da Asilia ouligisu dunu afae fonobahadidafa hasaliimu defele hame ba: sa. Amaiba: le, dilia abuliba: le Idibidi dunu da dilima sa: liode amola hosi da: iya fila heda: i dadi gagui dunu dilima asunasima: ne dawa: sala: ?
10 Síwájú sí i, ǹjẹ́ mo wa lè wá bá ilẹ̀ yìí jà kí n sì pa á run láìsí Olúwa? Olúwa fún rara rẹ̀ ló sọ pé kí n bá orílẹ̀-èdè yìí jà kí n sì pa á run.’”
Hina Gode da na fidibiba: le, na da dilia soge amo doagala: le wadela: lesi dagoi. Hina Gode Hisu da na asunasi dagoiba: le, na da agoane hamosu.”
11 Lẹ́yìn náà ni Eliakimu, Ṣebna àti Joah sọ fún ọ̀gágun náà pé, “Jọ̀wọ́ máa bá àwọn ìránṣẹ́ rẹ sọ̀rọ̀ ní èdè Aramaiki, nítorí pé àwa gbọ́ ọ. Má ṣe bá wa sọ̀rọ̀ ní èdè Heberu ní etí àwọn ènìyàn tí ó wà lórí ògiri mọ́.”
Amalalu, Ilaiagime amola Siebena amola Youa da amane sia: i, “Elama: igi sia: amoga ninima sia: ma! Ninia da amo sia: dawa: Hibulu sia: amoga mae sia: ma. Bai dunu huluane gagoi da: iya esalebe da nabasa: besa: le, Elama: igi sia: sia: ma.”
12 Ṣùgbọ́n aláṣẹ dáhùn pé, “Ṣé fún ọ̀gá rẹ àti ìwọ nìkan ní ọ̀gá mi rán mi sí láti sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí kì í sì í ṣe fún àwọn ọkùnrin tí ó jókòó lórí odi ni gẹ́gẹ́ bí ìwọ, ni yóò ní láti jẹ ìgbẹ́ ará wọn kí wọ́n sì mu ìtọ̀ ará wọn?”
Be Asilia ouligisu da bu adole i, “Dilia adi dawa: bela: ? Asilia hina bagade da dili amola Yuda hina bagade amo fawane nabima: ne, na hame asunasi. Hame mabu! Na da dunu huluane gagoi amoga esalebe ilima sia: sa. Bai ilia da dili defele ilila: iga manu amola ilila: baea manu.”
13 Lẹ́yìn náà ni ọ̀gágun náà dìde tí ó sì ké síta ní èdè Heberu pé, “Ẹ gbọ́ àwọn ọ̀rọ̀ ọba ńlá, ọba Asiria!
Amalalu, amo Asilia ouligisu dunu da wa: legadole amola Hibulu sia: amoga amane sia: i, “Nabima! Asilia hina bagade da dilima agoane sia: sa.
14 Ohun tí ọba wí nìyìí, Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekiah tàn yín jẹ. Òun kò le è gbà yín sílẹ̀!
E da dilima sisasu, amo Hesigaia ea ogogosu sia: mae nabima. Hesigaia da dili gaga: mu da hamedei.
15 Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekiah rọ̀ yín láti gbẹ́kẹ̀lé Olúwa nígbà tí ó sọ pé, ‘Olúwa yóò kúkú gbà wá; a kì yóò fi ìlú yìí lé ọba Asiria lọ́wọ́.’
Amola e da dilima Hina Gode da dili gaga: mu sia: sea, ea sia: mae nabima. Hina Gode da dili gaga: mu, amola ninia Asilia dadi gagui gilisisu ilia da dilia moilai bai bagade suguli lama: ne logo hedofamu, mae dawa: ma.
16 “Ẹ má ṣe tẹ́tí sí Hesekiah. Ohun tí ọba Asiria wí nìyìí. Ẹ fi ẹ̀bùn bá mi rẹ́, kí ẹ sì jáde tọ̀ mí wá. Lẹ́yìn náà, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín yóò sì jẹ nínú àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀ bẹ́ẹ̀ ni yóò sì mu omi nínú kànga rẹ̀,
Hesigaia ea sia: mae nabima. Asilia hina bagade da dilia huluane dilia moilai bai bagade fisili, gadili misini, ea se dabe iasu hawa: hamoma: ne sia: sa. Dilia da dilia waini sagai amola figi sagai amoga waini fage amola figi fage manu amola dilia si amoga hano manu.
17 títí tí èmi yóò fi mú un yín lọ sí ilẹ̀ kan tí ó dàbí i tiyín, ilẹ̀ tí ó ní irúgbìn oníhóró àti wáìnì tuntun, ilẹ̀ tí ó ní àkàrà àti ọgbà àjàrà.
Amasea, Asilia hina bagade da dili soge eno dilia soge agoane (amo ganodini da waini sagai amola gagoma dilia baledehamoma: ne) amoga fima: ne oule masunu.
18 “Ẹ má ṣe jẹ́ kí Hesekiah ṣì yín lọ́nà nígbà tí ó sọ wí pé, ‘Olúwa yóò gbà wá.’ Ǹjẹ́ ọlọ́run orílẹ̀-èdè kan ha ti gbà á kúrò lọ́wọ́ ọba Asiria bí?
Hesigaia ea sia: amo da Hina Gode da dili gaga: mu, amo da ogogosa. Mae nabima! Fifi asi gala eno huluane ilia ‘gode’ liligi da Asilia hina bagade ili mae hasanasima: ne gaga: bela: ? Hame mabu!
19 Níbo ni àwọn òrìṣà Hamati àti Arpadi ha wà? Níbo ni àwọn òrìṣà Sefarfaimi ha wà? Ǹjẹ́ wọn ti já Samaria gbà kúrò lọ́wọ́ mi bí?
Ha: ima: de amola Aba: de ilia ‘gode’ liligi da wali habila: ? Amola Sefafa: ime ilia ‘gode’ liligi ilia da habila: ? Nowa da Samelia fi gaga: bela: ?
20 Èwo nínú àwọn òrìṣà orílẹ̀-èdè wọ̀nyí ló ha ti dáàbò bo ilẹ̀ ẹ rẹ̀ kúrò lọ́wọ́ mi? Báwo ni Olúwa ṣe wá le gba Jerusalẹmu kúrò lọ́wọ́ mi?”
Amo soge ilia ‘gode’ liligi da ninia hina bagade ilima mae hasanasima: ne gaga: bela: ? Hame mabu! Amaiba: le, dilia da abuliba: le Hina Gode da Yelusaleme gaga: ma: ne defele esala, dawa: bela: ?”
21 Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn náà dákẹ́ rọ́rọ́ wọn kò sì mú èsì kankan wá, nítorí ọba ti pàṣẹ fún wọn pé, “Ẹ má ṣe dá a lóhùn.”
Be Yelusaleme fi dunu da hina bagade Hesigaia ea sia: defele ouiyale esalu. Ilia da sia: afadafa hame sia: i.
22 Lẹ́yìn náà ni Eliakimu ọmọ Hilkiah alákòóso ààfin, Ṣebna akọ̀wé àti Joah ọmọ Asafu akọ̀wé àkọsílẹ̀ lọ sí ọ̀dọ̀ Hesekiah pẹ̀lú aṣọ wọn ní fífàya, wọ́n sì sọ ohun tí ọ̀gágun ti wí.
Amalalu, Ilaiagime amola Siebena amola Youa da da: i dioiba: le, ilia abula gadelale, hina bagade Hesigaiama asili, Asilia ouligisu dunu ea sia: ema adole i.