< 1 Peter 2 >
1 Nítorí náà, ẹ fi àrankàn gbogbo sílẹ̀ ni apá kan, àti ẹ̀tàn gbogbo, àti àgàbàgebè, àti ìlara, àti sísọ ọ̀rọ̀ búburú gbogbo.
Amaiba: le, wadela: i hou huluane yolesima! Ogogosu hou, dabua fawane dafawaneyale dawa: su hou, mudasu hou amola gadesu sia: , amo huluane yolesima.
2 Bí ọmọ ọwọ́ tuntun, kí ẹ máa fẹ́ wàrà ti Ẹ̀mí, èyí tí kò lẹ́tàn, kí ẹ̀yin lè máa tipasẹ̀ rẹ̀ dàgbà sí ìgbàlà,
Dilia da gaheabolo lalelegei mano dudubu amo defele, a:silibu dodo maga: me hanaiba: le, amo nahabeba: le dilia da asigilale, gaga: sudafa hou ba: mu.
3 nísinsin yìí tí ẹ̀yin ti tọ́ ọ wò pé rere ni Olúwa.
Gode Sia: da agoane dedei, “Dilia dilisu da Gode Ea asigidafa hou hogobeba: le ba: i dagoi.”
4 Ẹni tí ẹ̀yin ń tọ̀ bọ̀, sí bi òkúta ààyè náà, èyí ti a ti ọwọ́ ènìyàn kọ̀ sílẹ̀ nítòótọ́, ṣùgbọ́n lọ́dọ̀ Ọlọ́run, àṣàyàn òkúta iyebíye.
Hina Gode da fedege agoane igi esala. Osobo bagade dunu ilia da amo igi da hamedei liligi dawa: beba: le, higa: i. Be Gode da amo igi noga: i ba: beba: le, Ema ilegei. Ema misa!
5 Ẹ̀yin pẹ̀lú, bí òkúta ààyè, ni a kọ́ ní ilé ẹ̀mí, àlùfáà mímọ́, láti máa rú ẹbọ ẹ̀mí, tí i ṣe ìtẹ́wọ́gbà lọ́dọ̀ Ọlọ́run nípa Jesu Kristi.
Gode da igi esala amoga fedege agoane a: silibu diasu gagulala. Dilia igi esala agoane, misa! Gode da ea diasu gagumusa: dili lale, dilia da Yesu Gelesuma madelagiba: le, hadigi gobele salasu dunu agoane, a:silibu gobele salasu Godema imunu. Amo Gode da hahawane ba: mu.
6 Nítorí nínú Ìwé Mímọ́, ó wí pe: “Kíyèsi i, mo fi pàtàkì òkúta igun ilé àṣàyàn, iyebíye, lélẹ̀ ni Sioni: ẹni tí ó bá sì gbà á gbọ́ ojú kì yóò tì í.”
Gode Sia: da agoane dedei diala, “Na da Igi ida: iwane gala ilegei. Amo Na da diasu baidafa agoane Saione moilai bai bagadega bugimu galebe. Nowa dunu da Ea hou lalegagusia, e da hame gogosiamu.”
7 Báyìí fún ẹ̀yin ti ẹ gbà á gbọ́, ó ṣe iyebíye; ṣùgbọ́n fún àwọn tí kò gbà á gbọ́, “Òkúta tí àwọn ọ̀mọ̀lé kọ̀sílẹ̀, òun ni ó di pàtàkì igun ilé,”
Dilia da amo Igi dafawaneyale dawa: beba: le, hahawane bagade ba: mu. Be nowa da dafawaneyale hame dawa: sea, Gode Sia: da agoane dedei diala, “Diasu gagusu dunu da amo Igi da hamedei liligi dawa: beba: le, fadegai dagoi. Be Gode da amo Igi baligili mimogodafa hamoi.”
8 àti pẹ̀lú, “Òkúta ìdìgbòlù, àti àpáta ìkọ̀sẹ̀.” Nítorí wọ́n kọsẹ̀ nípa ṣíṣe àìgbọ́ràn sí ọ̀rọ̀ náà, sínú èyí tí a gbé yàn wọ́n sí pẹ̀lú.
Gode Sia: eno da agoane dedei, “Dunu ilia da amo Igiga emo udagaguli dafamu!” Gode da amo hou hamomusa: dawa: beba: le, ilia Gode Ea sia: dafawaneyale hame dawa: beba: le, udagaguli dafai.
9 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ni ìran tí a yàn olú àlùfáà, Orílẹ̀-èdè mímọ́, ènìyàn ọ̀tọ̀ ki ẹ̀yin lè fi ọláńlá ẹni tí ó pè yín jáde kúrò nínú òkùnkùn sínú ìmọ́lẹ̀ ìyanu rẹ̀ hàn.
Be dilia da Gode Ea ilegei fi. Dilia da Hina Bagade Ea gobele salasu dunu. Dilia da Gode Hi fi dunu, hadigi fi hamoi. Gode da dili gasi yolesili, Ea hadigi ida: iwane amo ganodini esaloma: ne, dilima ilegei dagoi. E da Ea hou ida: iwane amo eno dunuma olelema: ne, dili asunasi.
10 Ẹ̀yin tí kì í ṣe ènìyàn nígbà kan rí, ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ẹ̀yin ti di ènìyàn Ọlọ́run, ẹ̀yin tí kò rí àánú gbà rí, ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ẹ ti rí àánú gbà.
Musa: dilia da Gode Ea fi dunu hame galu. Be wali dilia da Gode Ea fi dunu. Musa: dilia da Gode Ea gogolema: ne olofosu hame dawa: i galu. Be wali, E da iabeba: le, dilia da Gode Ea gogolema: ne olofosu lalegagui dagoi.
11 Olùfẹ́ ọ̀wọ́n, mo bẹ̀ yín, bí àjèjì àti àtìpó, láti fàsẹ́yìn kúrò nínú ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ara, tí ń ba ọkàn jagun.
Na fi dunu! Dilia da ga fi dunu agoane osobo bagadega esalebeba: le, na dilima ha: giwane edegesa. Dilia hu ea hanai hou amo da eso huluane dilia a: silibu amoma gegenana. Be dilia hu ea hou hasalima: ne, amo gegesu mae yolesima!
12 Kí ìwà yín láàrín àwọn aláìkọlà dára; pé, bí wọ́n ti ń sọ̀rọ̀ yín bí olùṣe búburú, nípa iṣẹ́ rere yín tí wọn ó máa kíyèsi, kí wọ́n lè máa yin Ọlọ́run lógo lọ́jọ́ ti òun ba bẹ̀ wá wò.
Gode Ea hou hame lalegagui dunu amo ilia gilisisu ganodini dilia hou da ida: iwane ba: mu da defea. Ilia da dili da wadela: i hamosu dunu ogogole sia: sa. Be dilia da noga: iwane hamobeba: le, amo ilia dawa: beba: le, Gode Ea bu misunu Esoga, ilia da dilima nodomu fawane.
13 Ẹ máa tẹríba fún gbogbo ìlànà ènìyàn nítorí ti Olúwa, ìbá à ṣe fún ọba tàbí fún olórí.
Dilia Hina Gode Ea hou lalegagui amo dawa: beba: le, osobo bagade ouligisu dunu ilia sia: nabawane hamoma. Louma hina bagade da osobo bagade hou amo ganodini hinadafa. Amaiba: le, dilia ea sia: nabima.
14 Tàbí fún àwọn baálẹ̀, fún àwọn tí a rán láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ láti gbẹ̀san lára àwọn tí ń ṣe búburú, àti fún ìyìn àwọn tí ń ṣe rere.
Amola eha eagene ouligisu dunu ilia wadela: i hamosu dunuma se dabe iasu ima: ne amola hou ida: iwane dunuma nodoma: ne, e da ili ilegei dagoi. Amaiba: le, dilia ilia sia: amolawane nabima.
15 Ìfẹ́ Ọlọ́run sá ni èyí pé, ní rere í ṣe, kí ẹ lè dẹ́kun ọ̀rọ̀ àìmọ̀kan òmùgọ̀ ènìyàn.
Bai Gode da agoane hanai galebe. Dilia hou ida: iwane hamobeba: le, gagaoui dunu ilia udigili sia: dasu logo da hedofai dagoi ba: mu.
16 Ẹ máa gbé gẹ́gẹ́ bí ẹni òmìnira, ṣùgbọ́n ẹ ma ṣe lo òmìnira yín láti bo ibi mọ́lẹ̀; ṣùgbọ́n kí ẹ gbé gẹ́gẹ́ bí ìránṣẹ́ Ọlọ́run.
Dilia udigili halegale lalebe dunu agoane esaloma! Be udigili halegale lalebeba: le, wadela: i hou dedeboma: ne mae hamoma. Be dilia Gode Ea udigili hawa: hamosu dunu defele esaloma!
17 Ẹ bọ̀wọ̀ fún gbogbo ènìyàn, ẹ fẹ́ àwọn ará, ẹ bẹ̀rù Ọlọ́run, ẹ bọ̀wọ̀ fún ọba.
Esega! Dunu huluanema asigima! Dilia Yesu Ea fi dunuma asigima! Godema beda: ma amola hina bagade dunu ilima nodoma!
18 Ẹ̀yin ọmọ ọ̀dọ̀, ẹ máa tẹríba fún àwọn ọ̀gá yín pẹ̀lú ìbẹ̀rù gbogbo, kì í ṣe fún àwọn ẹni rere àti oníwà tútù nìkan, ṣùgbọ́n fún àwọn òǹrorò pẹ̀lú.
Dilia hawa: hamosu dunu! Dilia ouligisu dunu ilia sia: nabawane hamoma amola ilima nodoma. Asigi ouligisu dunu amo fawane hame, be nimi bagade ouligisu dunu amola amo ea sia: nabawane hamoma.
19 Nítorí pé èyí ní ìgbóríyìn fún, bí ènìyàn bá fi ara da ìrora, ìjìyà lọ́nà àìtọ́, nítorí ọkàn rere sí Ọlọ́run.
Dilia da Gode Ea hanai hou dawa: beba: le, hou ida: iwane hamobeba: le mae hihini se nabasea, Gode da dilima hahawane dogolegesu hou olelemu.
20 Ṣùgbọ́n ògo kín ni ó jẹ́, nígbà tí ẹ ba ṣẹ̀ tí a sì lù yín, bí ẹ bá fi sùúrù gbà á? Ṣùgbọ́n nígbà tí ẹ̀yin bá ń ṣe rere tí ẹ sì ń jìyà, bí ẹ bá fi sùúrù gbà á, ẹ̀yín ní ọpẹ́ lọ́dọ̀ Ọlọ́run.
Be dilia wadela: i hou hamoiba: le se dabe iasu lasea, amo da dilima bidi imunu liligi hame. Be dilia hou ida: iwane hamobeba: le se iasu lasea mae hihini esalea, Gode da dilima hahawane dogolegele imunu.
21 Sí èyí ni a pè yín: nítorí Kristi pẹ̀lú jìyà fún un yin, ó fi àpẹẹrẹ sílẹ̀ fún un yín, kí ẹ̀yin lè máa tọ ipasẹ̀ rẹ̀:
Yesu Gelesu da dili fidima: ne se bagade nabi. Dilia da amo hou fa: no bobogema: ne, E da se nabi. Amo Yesu Ea se nabasu defele dili hamoma: ne, Gode da dilima ilegei dagoi.
22 “Òun kò dẹ́ṣẹ̀ kankan, bẹ́ẹ̀ sì ni, a kò rí ẹ̀tàn kan lẹ́nu rẹ̀.”
Yesu Gelesu da wadela: i hou hamedafa hamosu. Dunu afae da Ea lafidili ogogole sia: su hamedafa nabi.
23 Ẹni, nígbà tí a kẹ́gàn rẹ̀, tí kò sì padà kẹ́gàn; nígbà tí ó jìyà tí kò sì halẹ̀; ṣùgbọ́n ó fi ọ̀ràn rẹ̀ lé ẹni ti ń ṣe ìdájọ́ òdodo lọ́wọ́.
Dunu eno da Ema gadele sia: noba, E da bu dabe hame gadei. E da se nabaloba, E da dabemu mae sia: ne, be Gode (Moloidafa Fofada: su Dunu) amo da E fidimu E dawa: beba: le, E da dafawaneyale hamoma: beyale dawa: i.
24 Ẹni tí òun tìkára rẹ̀ fi ara rẹ̀ ru ẹ̀ṣẹ̀ wa lórí igi àgbélébùú, pé kí àwa lè di òkú sí ẹ̀ṣẹ̀, ki a sì di ààyè sí òdodo, nípa ìjìyà ẹni tí ó mú yín láradá.
Yesu Gelesu da ninia wadela: i hou huluane Ea da: iga lalegaguli, ifa bulufalegeiga bogoi. Ninia da wadela: i hou amoma bogole, bu hou moloidafa hamomusa: esaloma: ne, Yesu da bogoi dagoi. Yesu Ea fofa: gi amoga ninia da uhi dagoi.
25 Nítorí tí ẹ̀yin ń ṣáko lọ bí àgùntàn, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ẹ̀yin ti padà sí ọ̀dọ̀ olùṣọ́-àgùntàn àti bíṣọ́ọ̀bù ọkàn yín.
Dilia da sibi fisi agoane ba: su. Be Sibi Ouligisu da dili bu oule misi dagoi. Sibi Ouligisu amo da dilia a: silibu ouligisa. Dilia da Ema fa: no bobogema: ne, E da dili bu oule misi.