< 1 Chronicles 14 >
1 Nísinsin yìí Hiramu àti ọba Tire rán oníṣẹ́ sí Dafidi, àti pẹ̀lú igi kedari pẹ̀lú àwọn ọ̀mọ̀lé àti gbẹ́nàgbẹ́nà láti kọ́ ààfin fún un.
Külde pedig Hírám, Tírus királya Dávidhoz követeket: czédrusfákat, kőmíveseket és ácsmestereket, hogy néki házat csináljanak.
2 Dafidi sì mọ Israẹli àti pé Olúwa ti fi òun ṣe ọba lórí Israẹli àti pé ìjọba rẹ̀ ga jùlọ nítorí ti àwọn ènìyàn rẹ̀.
És megismeré Dávid, hogy az Úr őt megerősítette a királyságban Izráel felett, mivelhogy igen felmagasztaltatott vala az ő országa az ő népéért, az Izráelért.
3 Ní Jerusalẹmu Dafidi mú ọ̀pọ̀ ìyàwó ó sì di baba àwọn ọmọ ọkùnrin púpọ̀ àti ọmọbìnrin.
Vőn pedig Dávid még több feleséget Jeruzsálemben, és nemze Dávid még több fiakat és leányokat.
4 Èyí ni orúkọ àwọn ọmọ náà tí wọ́n bí fún un níbẹ̀: Ṣammua, Ṣobabu, Natani, Solomoni,
És ezek neveik azoknak, a kik születtek néki Jeruzsálemben: Sammua, Sobáb, Nátán és Salamon,
5 Ibhari, Eliṣua, Elifeleti,
Ibhár, Elisua és Elpélet,
7 Eliṣama, Beeliada, àti Elifeleti.
Elisáma, Beheljada és Elifélet.
8 Nígbà tí àwọn ará Filistini gbọ́ pé a ti fi àmì òróró yàn Dafidi ní ọba lórí gbogbo Israẹli, wọ́n sì lọ sókè pẹ̀lú ipá láti wá a rí, ṣùgbọ́n Dafidi gbọ́ nípa rẹ̀ ó sì jáde lọ láti pàdé wọn.
Megértvén pedig a Filiszteusok, hogy Dávid királylyá kenetett fel az egész Izráel felett, feljövének mind a Filiszteusok, hogy megkeressék Dávidot. Mely dolgot mikor Dávid meghallott, azonnal ellenök ment.
9 Nísinsin yìí àwọn ará Filistini ti wá láti gbógun ti àfonífojì Refaimu;
A Filiszteusok pedig eljövén, elszéledének a Réfaim völgyében.
10 Dafidi sì béèrè lọ́dọ̀ Ọlọ́run wí pé, “Kí èmi kí ó gòkè tọ àwọn ará Filistini lọ bí? Ìwọ ó ha fi wọ́n lé mi lọ́wọ́?” Olúwa sì wí fún un pé, “Gòkè lọ èmi ó sì fi wọ́n lé ọ lọ́wọ́.”
Akkor Dávid megkérdé az Istent, mondván: Felmenjek-é a Filiszteusok ellen, és kezembe adod-é őket? És monda néki az Úr: Menj fel, és kezedbe adom őket.
11 Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi àti àwọn ènìyàn rẹ̀ gòkè lọ sí Baali-Perasimu, níbẹ̀ ó sì kọlù wọ́n. Ó sí wí pé, “Gẹ́gẹ́ bí omi tí ya jáde, Ọlọ́run ti ya Dafidi lórí àwọn ọ̀tá mi pẹ̀lú ọwọ́ mi.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń pè ibẹ̀ ní Baali-Perasimu.
Felmenének azért Baál-perásimba, és ott Dávid őket megveré, és monda Dávid: Az Isten eloszlatá az én ellenségeimet az én kezem által, mint a vizeknek oszlását; azért nevezék azt a helyet Baál-perásimnak.
12 Àwọn ará Filistini sì ti fi àwọn òrìṣà wọn sílẹ̀ níbẹ̀. Dafidi sì pa á láṣẹ láti jó wọn nínú iná.
És ott hagyák az ő bálvány isteneiket, és Dávid megparancsolá, hogy megégessék azokat.
13 Lẹ́ẹ̀kan sí i àwọn ará Filistini gbógun wọ́n sì fọ́nká àfonífojì,
Ismét feltámadának a Filiszteusok és a völgyben szétterjeszkedtek.
14 Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi sì tún béèrè lọ́wọ́ Ọlọ́run, Ọlọ́run sì dalóhùn pé, “Má ṣe gòkè tààrà, ṣùgbọ́n ẹ yí wọn ká, kí ẹ sì mú wọn níwájú igi muliberi.
Azért Dávid ismét megkérdé az Istent, és monda az Isten néki: Ne menj fel utánok, hanem fordulj el tőlök, és menj reájok a szederfák irányában;
15 Tí ó bá sì ṣe, tí ẹ̀yin bá ti gbọ́ ìró ẹsẹ̀ ní orí òkè igi muliberi, ẹ jáde fún ogun, nítorí èyí yóò fihàn pé Ọlọ́run ti jáde níwájú rẹ láti kọlu àwọn ọmọ-ogun Filistini.”
És mikor hallándod a járás dobogását a szederfák tetején, akkor menj ki a viadalra; mert az Isten te előtted megyen, hogy megverje a Filiszteusok táborát.
16 Bẹ́ẹ̀ ni Dafidi ṣe ohun tí Ọlọ́run ti pàṣẹ fún wọn, wọ́n sì kọlu àwọn ọmọ-ogun Filistini láti gbogbo ọ̀nà Gibeoni lọ sí Geseri.
Dávid azért úgy cselekedék, a mint néki Isten meghagyta volt, és vágák a Filiszteusok táborát Gibeontól fogva szinte Gézerig.
17 Bẹ́ẹ̀ ni òkìkí Dafidi tàn ká gbogbo ilẹ̀ káàkiri, Olúwa sì mú kí gbogbo orílẹ̀-èdè bẹ̀rù rẹ̀.
És elterjede Dávid híre az országokban, és az Úr adá a tőle való félelmet minden pogányokra.