< Nnwom 51 >

1 Dawid dwom a ɔtoo no bere a ɔde ne ho kaa Batseba na odiyifo Natan kɔɔ ne nkyɛn no. Ao, Onyankopɔn hu me mmɔbɔ, sɛnea wʼadɔe a ɛnsa da no te; wʼahummɔbɔ kɛse no nti, pepa me mmarato.
Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Nígbà ti wòlíì Natani tọ wá, lẹ́yìn tí Dafidi dá ẹ̀ṣẹ̀ àgbèrè rẹ̀ pẹ̀lú Batṣeba. Ṣàánú fún mi, Ọlọ́run, gẹ́gẹ́ bí ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ọ̀pọ̀ àánú rẹ̀ kí o sì pa gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi rẹ́.
2 Hohoro mʼamumɔyɛ nyinaa na tew me ho fi me bɔne mu!
Wẹ gbogbo àìṣedéédéé mi nù kúrò kí o sì wẹ̀ mi mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ mi!
3 Na mahu me mmarato, na mekae me bɔne daa.
Nítorí mo mọ̀ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi, nígbà gbogbo ni ẹ̀ṣẹ̀ mi wà níwájú mi.
4 Mayɛ mfomso atia wo; atia wo nko ara na mayɛ nea ɛyɛ bɔne wɔ wʼani so, enti wudi bem wɔ wʼatemmu mu na woteɛ wɔ wʼatemmu mu.
Sí ọ, ìwọ nìkan ṣoṣo, ni mo dẹ́ṣẹ̀ sí ni mo sì ṣe búburú níwájú rẹ̀, kí a lè dá ọ láre nígbà tí ìwọ bá ń sọ̀rọ̀, kí o sì le wà láìlẹ́bi, nígbà tí ìwọ bá ń ṣe ìdájọ́.
5 Ampa ara wɔwoo me wɔ bɔne mu, na bɔne mu na me na nyinsɛn me.
Nítòótọ́, nínú ẹ̀ṣẹ̀ ni a ti bí mi, nínú ẹ̀ṣẹ̀ ni ìyá mí sì lóyún mi.
6 Ampa ara nokware na wohwehwɛ wɔ me mu. Wokyerɛ me nyansa a mu dɔ.
Nítòótọ́ ìwọ fẹ́ òtítọ́ ní inú; ìwọ kọ́ mi ní ọgbọ́n ní ìhà ìkọ̀kọ̀.
7 Fa adwerɛ hohoro me ho, na me ho afi; guare me, na mɛhoa asen sukyerɛmma.
Wẹ̀ mí pẹ̀lú ewé hísópù, èmi yóò sì mọ́; fọ̀ mí, èmi yóò sì funfun ju yìnyín lọ.
8 Ma mente ahosɛpɛw ne anigye nka; na ma nnompe a woabubu no nni ahurusi.
Jẹ́ kí n gbọ́ ayọ̀ àti inú dídùn; jẹ́ kí gbogbo egungun tí ìwọ ti run kí ó máa yọ̀.
9 Kata wʼani wɔ me bɔne ho na pepa mʼamumɔyɛ nyinaa.
Pa ojú rẹ̀ mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ mi kí o sì pa gbogbo àwọn àìṣedéédéé mi rẹ́.
10 Ao, Onyankopɔn, bɔ koma a mu tew wɔ me mu, na yɛ honhom a atim no foforo wɔ me mu.
Dá ọkàn mímọ́ sí inú mi, Ọlọ́run, kí o sì tún ẹ̀mí dídúró ṣinṣin ṣe sínú mi.
11 Mpam me mfi wʼanim, na nyi wo Honhom Kronkron mfi me mu.
Má ṣe jù mi nù kúrò níwájú rẹ, kí o má ṣe gba Ẹ̀mí Mímọ́ rẹ lọ́wọ́ mi.
12 Fa wo nkwagye mu anigye no ma me bio, na ma me ɔpɛ honhom a ɛbɛma magyina.
Mú ayọ̀ ìgbàlà rẹ tọ̀ mí wá, kí o sì fún mi ní ẹ̀mí ìfẹ́, tí yóò mú mi dúró.
13 Afei mɛkyerɛ nnebɔneyɛfo wʼakwan, na amumɔyɛfo bɛsan aba wo nkyɛn.
Nígbà náà ni èmi yóò máa kọ́ àwọn olùrékọjá ní ọ̀nà rẹ, àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ yóò sì yí padà sí ọ.
14 Ao, Onyankopɔn, gye me fi mogya ho afɔdi mu. Onyame a wugye me nkwa, na me tɛkrɛma bɛto wo trenee ho dwom.
Gbà mí kúrò lọ́wọ́ ẹ̀bi ẹ̀jẹ̀, Ọlọ́run, ìwọ Ọlọ́run ìgbàlà mi, ahọ́n mi yóò sì máa kọrin òdodo rẹ kíkan.
15 Awurade, bue mʼano fafa, na mede mʼano bɛpae mu aka wʼayeyi.
Olúwa, ṣí mi ní ètè mi gbogbo, àti ẹnu mi yóò sì máa kéde ìyìn rẹ.
16 Wompɛ afɔrebɔ, anka mɛbɔ; wʼani nnye ɔhyew afɔre ho.
Nítorí ìwọ kò ní inú dídùn sí ẹbọ, tí èmi kò bá mú wá; Ìwọ kò ní inú dídùn sí ọrẹ ẹbọ sísun.
17 Onyankopɔn afɔre yɛ honhom a abotow, Onyankopɔn, worempo ahonu ne ahobrɛase koma.
Ẹbọ Ọlọ́run ni ìròbìnújẹ́ ọkàn ìròbìnújẹ́ àti ìrora àyà.
18 Ma ɛnyɛ wo fɛ sɛ wobɛma Sion anya nkɔso wɔ wʼanigye mu; na woasi Yerusalem afasu.
Ṣe rere ní dídùn inú rẹ sí Sioni, ṣe rere; tún odi Jerusalẹmu mọ.
19 Afei wʼani begye ɔtreneeni afɔrebɔ ho, ɔhyew afɔre a edi mu; na wɔde anantwinini bɛbɔ afɔre wʼafɔremuka so. Wɔde ma dwonkyerɛfo.
Nígbà náà ni inú rẹ yóò dùn sí ẹbọ òdodo, pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun àti ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ ọrẹ ẹbọ sísun, nígbà náà ni wọn yóò fi akọ màlúù rú ẹbọ lórí pẹpẹ rẹ.

< Nnwom 51 >