< Kwadwom 3 >

1 Mene ɔbarima a mahu amane wɔ nʼabufuw abaa ano.
Èmi ni ọkùnrin tí ó rí ìpọ́njú pẹ̀lú ọ̀pá ìbínú rẹ.
2 Wapam me afi ne ho ama manantew sum mu na ɛnyɛ hann mu;
Ó ti lé mi jáde ó sì mú mi rìn nínú òkùnkùn ju ti ìmọ́lẹ̀.
3 Ampa ara wama nsa so atia me mpɛn bebree, da mu nyinaa.
Nítòótọ́, ó ti yí ọwọ́ rẹ̀ padà sí mi síwájú àti síwájú sí i ní gbogbo ọjọ́.
4 Wama me were ne me nam anyin Na wabubu me nnompe.
Ó jẹ́ kí àwọ̀ mi àti ẹran-ara mi gbó ó sì tún ṣẹ́ egungun mi.
5 Waka me ahyɛ mu, na watua me ano ɔde nweenwen ne ahokyere atwa me ho ahyia.
Ó ti fi mí sí ìgbèkùn, ó sì ti yí mi ká pẹ̀lú ìkorò àti làálàá.
6 Wama matena sum mu sɛ wɔn a wɔawuwu dedaw no.
Ó mú mi gbé nínú òkùnkùn, bí ti àwọn tó ti kú fún ìgbà pípẹ́.
7 Wato ɔfasu atwa me ho ahyia enti mintumi nguan; wagu me nkɔnsɔnkɔnsɔn ama matɔ beraw.
Ó ti tì mí mọ́ ilé, nítorí náà n kò le è sálọ; ó ti fi ẹ̀wọ̀n mú mi mọ́lẹ̀.
8 Mpo sɛ mefrɛ anaasɛ mebɔ mpae srɛ mmoa a osiw me mpaebɔ ano.
Pàápàá nígbà tí mo ké fún ìrànlọ́wọ́, ó kọ àdúrà mi.
9 Ɔde abotan asiw me kwan; wama mʼakwan ayɛ kɔntɔnkye.
Ó fi ògiri òkúta dí ọ̀nà mi; ó sì mú ọ̀nà mi wọ́.
10 Te sɛ sisi a ɔda hɔ retwɛn, te sɛ gyata a watɛw,
Bí i beari tí ó dùbúlẹ̀, bí i kìnnìún tí ó sá pamọ́.
11 ɔtwee me fii ɔkwan no mu bebaree me na ogyaw me a minni mmoa biara.
Ó wọ́ mi kúrò ní ọ̀nà, ó tẹ̀ mí mọ́lẹ̀ ó fi mi sílẹ̀ láìsí ìrànlọ́wọ́.
12 Okuntun ne ta mu na ɔde ne bɛmma kyerɛɛ me so.
Ó fa ọfà rẹ̀ yọ ó sì fi mí ṣe ohun ìtafàsí.
13 Ɔde bɛmma a efi ne kotoku mu hwirew me koma mu.
Ó fa ọkàn mí ya pẹ̀lú ọfà nínú àkọ̀ rẹ̀.
14 Meyɛɛ akyiwade maa me nkurɔfo nyinaa; wɔto akutia nnwom de di me ho fɛw da mu nyinaa.
Mo di ẹni yẹ̀yẹ́ láàrín àwọn ènìyàn mi; wọn yẹ̀yẹ́ mi pẹ̀lú orin ní gbogbo ọjọ́.
15 Ɔde nhaban nweenwen ahyɛ me ma. Wama me bɔnwoma anom.
Ó ti kún mi pẹ̀lú ewé kíkorò àti ìdààmú bí omi.
16 Ɔde mmosea abubu me se; na watiatia me so wɔ mfutuma mu.
Ó ti fi òkúta kán eyín mi; ó ti tẹ̀ mí mọ́lẹ̀ nínú eruku.
17 Wɔama asomdwoe abɔ me; na me werɛ afi yiyedi.
Mo ti jìnnà sí àlàáfíà; mo ti gbàgbé ohun tí àṣeyege ń ṣe.
18 Enti mise, “Mʼanuonyam asa, nea mede mʼani too so Awurade mu no nyinaa.”
Nítorí náà mo wí pé, “Ògo mi ti lọ àti ìrètí mi nínú Olúwa.”
19 Mekae mʼamanehunu wɔ mʼakyinkyinakyinkyin mu, nweenwen ne bɔnwoma mu.
Mo ṣe ìrántí ìpọ́njú àti ìdààmú mi, ìkorò àti ìbànújẹ́.
20 Mekae yiye, na me kra abotow wɔ me mu.
Mo ṣèrántí wọn, ọkàn mi sì gbọgbẹ́ nínú mi.
21 Nanso midwen eyi ho; saa nti mewɔ anidaso.
Síbẹ̀, èyí ni mo ní ní ọkàn àti nítorí náà ní mo nírètí.
22 Awurade dɔ kɛse nti yɛnsɛee ɛ. Nʼayamhyehye nni huammɔ.
Nítorí ìfẹ́ Olúwa tí ó lágbára ni àwa kò fi ṣègbé, nítorí ti àánú rẹ kì í kùnà.
23 Ɛyɛ foforo anɔpa biara; wo nokwaredi yɛ kɛse.
Wọ́n jẹ́ ọ̀tún ní àárọ̀; títóbi ni òdodo rẹ̀.
24 Meka kyerɛ me ho se, “Awurade yɛ me kyɛfa, enti mɛtwɛn no.”
Mo wí fún ara mi, ìpín mi ni Olúwa; nítorí náà èmi yóò dúró dè ọ́.
25 Awurade ye ma wɔn a wɔn anidaso wɔ ne mu, onipa a ɔhwehwɛ no no;
Dídára ni Olúwa fún àwọn tí ó ní ìrètí nínú rẹ̀, sí àwọn tí ó ń wá a.
26 Eye sɛ wɔyɛ komm de twɛn Awurade nkwagye.
Ó dára kí a ní sùúrù fún ìgbàlà Olúwa.
27 Eye ma ɔbarima sɛ ɔsoa konnua no wɔ ne mmerantebere mu.
Ó dára fún ènìyàn láti gbé àjàgà nígbà tí ó wà ní èwe.
28 Ma ɔntena ase komm, efisɛ Awurade de ato ne so.
Jẹ́ kí ó jókòó ní ìdákẹ́ jẹ́ẹ́, nítorí Olúwa ti fi fún un.
29 Ma ɔmfa nʼanim nsie wɔ mfutuma mu, ebia anidaso wɔ hɔ.
Jẹ́ kí ó bo ojú rẹ̀ sínú eruku— ìrètí sì lè wà.
30 Ma ɔmfa nʼafono mma nea ɔpɛɛ sɛ ɔbɔ no no na ɔnhyɛ no aniwu.
Jẹ́ kí ó fi ẹ̀rẹ̀kẹ́ fún àwọn tí yóò gbá a, sì jẹ́ kí ó wà ní ìdójútì.
31 Na Awurade ntow onipa biara nkyene koraa.
Ènìyàn kò di ìtanù lọ́dọ̀ Olúwa títí láé.
32 Ɛwɔ mu, ɔde awerɛhow ba de, nanso obenya ayamhyehye. Ne dɔ kɛse no to rentwa da.
Lóòtítọ́ ó mú ìbànújẹ́ wá, yóò fi àánú hàn, nítorí títóbi ni ìfẹ́ rẹ̀.
33 Ofi amemenemfe mu de amanehunu anaa awerɛhow brɛ nnipa mma.
Nítorí kò mọ̀ ọ́n mọ̀ mú ìpọ́njú wá tàbí ìrora wá fún ọmọ ènìyàn.
34 Sɛ wɔde wɔn nan dwerɛw nneduafo a wɔwɔ asase no so a,
Láti tẹ mọ́lẹ̀ lábẹ́ ẹsẹ̀ gbogbo àwọn ẹlẹ́wọ̀n ní ilẹ̀ náà.
35 sɛ wotiatia obi ahofadi so wɔ Ɔsorosoroni no anim a,
Láti ṣẹ́ ọmọ ènìyàn fún ẹ̀tọ́ rẹ̀ níwájú Ọ̀gá-ògo jùlọ,
36 anaa sɛ wobu obi ntɛnkyew a, Awurade renhu saa nneɛma yi ana?
láti yí ìdájọ́ ènìyàn padà, ǹjẹ́ Olúwa kò rí ohun bẹ́ẹ̀.
37 Hena na obetumi aka na wama aba mu wɔ bere a ɛnyɛ Awurade na ɔhyɛe?
Ta ni yóò sọ̀rọ̀ tí yóò rí bẹ́ẹ̀ tí Olúwa kò bá fi àṣẹ sí i.
38 Ɛnyɛ Ɔsorosoroni no anom na mmusu ne nnepa fi ana?
Ǹjẹ́ kì í ṣe láti ẹnu Ọ̀gá-ògo jùlọ ni rere àti búburú tí ń wá?
39 Adɛn nti na ɛsɛ sɛ ɔteasefo nwiinwii bere a wɔatwe nʼaso wɔ ne bɔne ho?
Kí ló dé tí ẹ̀dá alààyè ṣe ń kùn nígbà tí ó bá ń jìyà ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀?
40 Momma yɛnhwehwɛ yɛn akwan mu na yɛnsɔ nhwɛ, na yɛnsan nkɔ Awurade nkyɛn.
Ẹ jẹ́ kí a yẹ ọ̀nà wa, kí a sì dán an wò, kí a sì tọ Olúwa lọ.
41 Momma yɛmma yɛn koma ne yɛn nsa so, nkyerɛ Onyankopɔn wɔ ɔsoro, na yɛnka se:
Ẹ jẹ́ kí a gbé ọkàn àti ọwọ́ wa sókè sí Ọlọ́run ní ọ̀run, kí a wí pé,
42 “Yɛayɛ bɔne, na yɛatew atua na wamfa ankyɛ.
“Àwa ti ṣẹ̀ a sì ti ṣọ̀tẹ̀ ìwọ kò sì fi ẹ̀ṣẹ̀ wa jì wá.
43 “Wode abufuw akata wo ho ataa yɛn; na woakunkum a woannya ahummɔbɔ.
“Ìwọ fi ìbínú bo ara rẹ ìwọ sì ń lépa wa; ìwọ ń parun láìsí àánú.
44 Wode wo ho asie omununkum mu nti mpaebɔ biara nnu wo nkyɛn.
Ìwọ ti fi àwọsánmọ̀ bo ara rẹ pé kí àdúrà wa má ba à dé ọ̀dọ̀ rẹ.
45 Woayɛ yɛn atantanne ne nwura wɔ amanaman no mu.
Ó ti sọ wá di èérí àti ààtàn láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.
46 “Yɛn atamfo nyinaa abaa wɔn anom tɛtrɛɛ de tia yɛn.
“Gbogbo àwọn ọ̀tá wa ti la ẹnu wọn gbòòrò sí wa.
47 Yɛabrɛ ne ahunahuna ne akukuruhwease, mmubui ne ɔsɛe.”
Àwa ti jìyà àti ìparun, nínú ìbẹ̀rù àti ewu.”
48 Me nusu sen sɛ asuten efisɛ wɔasɛe me nkurɔfo.
Omijé ń sàn ní ojú mi bí odò nítorí a pa àwọn ènìyàn mi run.
49 Me nusu bɛsen ara, na ɛrennyae,
Ojú mi kò dá fún omijé, láì sinmi,
50 kosi sɛ Awurade bɛhwɛ afi ɔsoro, na wahu.
títí ìgbà tí Olúwa yóò síjú wolẹ̀ láti òkè ọ̀run tí yóò sì rí i.
51 Nea mihu no ma me kra werɛ how, me kuropɔn no mu mmea nyinaa nti.
Ohun tí mo rí mú ìbẹ̀rù wá ọkàn mi nítorí gbogbo àwọn obìnrin ìlú mi.
52 Mʼatamfo a menyɛɛ wɔn hwee pampam me sɛ anomaa.
Àwọn tí ó jẹ́ ọ̀tá mi láìnídìí dẹ mí bí ẹyẹ.
53 Wɔpɛɛ sɛ wotwa me nkwa so na wosiw me abo wɔ amoa mu;
Wọ́n gbìyànjú láti mú òpin dé bá ayé mi nínú ihò wọ́n sì ju òkúta lù mí.
54 nsu bu faa me ti so, na ɛyɛɛ me sɛnea wɔrewie me.
Orí mi kún fún omi, mo sì rò pé ìgbẹ̀yìn dé.
55 Mebɔɔ wo din, Awurade fii amoa no ase tɔnn.
Mo pe orúkọ rẹ, Olúwa, láti ọ̀gbun ìsàlẹ̀ ihò.
56 Wotee me sufrɛ: “Nsiw wʼaso wɔ me gye sufrɛ ho.”
Ìwọ gbọ́ ẹ̀bẹ̀ mi, “Má ṣe di etí rẹ sí igbe ẹ̀bẹ̀ mi fún ìtura.”
57 Wutwiw bɛn me bere a mefrɛɛ wo no, na wokae se, “Nsuro.”
O wá tòsí nígbà tí mo ké pè ọ́, o sì wí pé, “Má ṣe bẹ̀rù.”
58 Wo Awurade, wudii mʼasɛm maa me; na wugyee me nkwa.
Olúwa, ìwọ gba ẹjọ́ mi rò, o ra ẹ̀mí mi padà.
59 Woahu bɔne a wɔayɛ me, Awurade. Di mʼasɛm ma me!
O ti rí i, Olúwa, búburú tí a ṣe sí mi. Gba ẹjọ́ mi ró!
60 Woahu wɔn aweretɔ no mu den, wɔn pɔw a wɔbɔ tia me no nyinaa.
Ìwọ ti rí ọ̀gbun ẹ̀san wọn, gbogbo ìmọ̀ wọn sí mi.
61 Awurade, woate wɔn ntwirii, wɔn pɔw a wɔbɔ tia me no nyinaa,
Olúwa ìwọ ti gbọ́ ẹ̀gàn wọn àti ìmọ̀ búburú wọn sí mi,
62 nea mʼatamfo ka no asomsɛm na wɔka no brɛoo de tia me da mu nyinaa.
ohun tí àwọn ọ̀tá mi ń sọ sí mi ní gbogbo ọjọ́.
63 Hwɛ wɔn! Sɛ wogyinagyina hɔ anaasɛ wɔtete hɔ, wɔto akutia nnwom de di me ho fɛw.
Wò wọ́n! Ní jíjòkòó tàbí ní dídìde, wọ́n ń ṣẹlẹ́yà mi nínú orin wọn.
64 Fa nea ɛfata tua wɔn so ka, Awurade, nea wɔn nsa ayɛ nti.
Olúwa san wọ́n lẹ́san ohun tí ó tọ́ sí wọn fún ohun tí ọwọ́ wọn ti ṣe.
65 Pirim wɔn koma, na ma wo nnome mmra wɔn so.
Fi ìbòjú bò wọ́n ní ọkàn, kí o sì fi wọ́n ré.
66 Fa abufuw taa wɔn, na sɛe wɔn fi Awurade ɔsorosoro ase.
Ni wọ́n lára kí o sì pa wọ́n run pẹ̀lú ìbínú, lábẹ́ ọ̀run Olúwa.

< Kwadwom 3 >