< Salmos 101 >

1 Haré una canción de misericordia y justicia; a ti, oh Señor, haré melodía.
Ti Dafidi. Saamu. Èmi yóò kọrin ìfẹ́ àti òdodo; sí ọ Olúwa, èmi yóò máa kọrin ìyìn.
2 Andare sabiamente en el camino de la justicia: ¿cuándo vendrás a mí? Estaré caminando en mi casa con un corazón verdadero.
Èmi yóò máa rin ìrìn mi pẹ̀lú ọgbọ́n láìlẹ́ṣẹ̀, ìgbà wo ni ìwọ yóò wá sí ọ̀dọ̀ mi? Èmi yóò máa rìn ní ilé mi pẹ̀lú àyà pípé.
3 No pondré ningún mal ante mis ojos; Estoy en contra de que todos se vuelvan hacia un lado; No lo tendré cerca de mí.
Èmi kì yóò gbé ohun búburú sí iwájú mi: iṣẹ́ àwọn tí ó yapa ni èmi kórìíra. Wọn kì yóò rọ̀ mọ́ mi.
4 El corazón falso lo enviaré lejos: No tendré un malhechor para un amigo.
Agídí ọkàn yóò kúrò lọ́dọ̀ mi; èmi kì yóò mọ ènìyàn búburú.
5 Daré muerte a cualquiera que diga en secreto el mal de su prójimo; el hombre con una mirada alta y un corazón de orgullo es repugnante para mí.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń sọ̀rọ̀ ẹnìkejì rẹ̀ ní ìkọ̀kọ̀, òun ní èmi yóò gé kúrò ẹni tí ó bá gbé ojú rẹ̀ ga tí ó sì ní ìgbéraga àyà, òun ní èmi kì yóò faradà fún.
6 Mis ojos estarán puestos en los que tienen buena fe en la tierra, para que vivan en mi casa; el que anda por el camino correcto será mi siervo.
Ojú mi yóò wà lára àwọn olóòtítọ́ lórí ilẹ̀, kí wọn kí ó lè máa bá mi gbé; ẹni tí ó bá n rin ọ̀nà pípé òun ni yóò máa sìn mí.
7 El obrero del engaño no entrará en mi casa; el hombre falso no tendrá lugar ante mis ojos.
Ẹni tí ó bá ń ṣe ẹ̀tàn, kì yóò gbé ilé mi, kò sí ẹni tí ń ṣèké tí yóò dúró ní iwájú mi.
8 Día tras día destruiré a todos los pecadores en la tierra, para que todos los malvados puedan ser separados de Jerusalén.
Ní ojoojúmọ́ ní èmi yóò wá máa pa a lẹ́nu mọ gbogbo àwọn ènìyàn búburú ilẹ̀ náà; èmi yóò gé àwọn olùṣe búburú kúrò ní ìlú Olúwa.

< Salmos 101 >