< Hioba 17 >
1 Mój oddech jest skażony, moje dni gasną, groby na mnie [czekają].
“Ẹ̀mí mi bàjẹ́, ọjọ́ mi ni a ti gé kúrú, isà òkú dúró dè mí.
2 Czy nie szydercy są przy mnie? Czy moje oko nie czuwa przez ich zniewagi?
Nítòótọ́ àwọn ẹlẹ́yà wà lọ́dọ̀ mi, ojú mi sì tẹ̀mọ́ ìmúnibínú wọn.
3 Złóż więc zastaw za mnie u siebie. Któż jest ten, który za mnie poręczy?
“Fi fún mi Olúwa, ìlérí tí ìwọ fẹ́; ta ni yóò le ṣe ààbò fún mi?
4 Ich serce bowiem ukryłeś przed zrozumieniem, dlatego [ich] nie wywyższysz.
Nítorí pé ìwọ ti sé wọ́n láyà kúrò nínú òye; nítorí náà ìwọ kì yóò gbé wọn lékè.
5 Kto pochlebia przyjaciołom, tego dzieciom zgasną oczy.
Ẹni tí ó sọ ọ̀rọ̀ ẹ̀tàn dídún fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ fún èrè, òun ni ojú àwọn ọmọ rẹ̀ yóò mú òfo.
6 Uczynił mnie tematem przysłowia wśród ludzi i pośmiewiskiem przed nimi.
“Ọlọ́run ti sọ mi di ẹni òwe fún àwọn ènìyàn; níwájú wọn ni mo dàbí ẹni ìtutọ́ sí ní ojú.
7 Moje oko zaćmiło się od smutku, a wszystkie moje członki są jak cień.
Ojú mí ṣú bàìbàì nítorí ìbìnújẹ́, gbogbo ẹ̀yà ara mi sì dàbí òjìji.
8 Prawi zdumieją się nad tym, a niewinny powstanie przeciwko obłudnikowi.
Àwọn olódodo yóò yanu sí èyí, ẹni aláìṣẹ̀ sì bínú sí àwọn àgàbàgebè.
9 Sprawiedliwy będzie trwał przy swojej drodze, a kto ma czyste ręce, nabierze siły.
Olódodo pẹ̀lú yóò di ọ̀nà rẹ̀ mú, àti ọlọ́wọ́ mímọ́ yóò máa lera síwájú.
10 Lecz wy wszyscy zawróćcie i przyjdźcie; bo mądrego wśród was nie znajduję.
“Ṣùgbọ́n bí ó ṣe ti gbogbo yín, ẹ yípadà, kí ẹ si tún padà nísinsin yìí; èmi kò le rí ọlọ́gbọ́n kan nínú yín.
11 Moje dni przeminęły, rozwiały się moje zamiary, myśli mego serca.
Ọjọ́ tí èmi ti kọjá, ìrò mi ti fà yá, àní ìrò ọkàn mi.
12 Noc zamieniają w dzień, światłość skraca się z powodu ciemności.
Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń ṣọ́ òru di ọ̀sán; wọ́n ní, ìmọ́lẹ̀ súnmọ́ ibi tí òkùnkùn dé.
13 Gdybym czegoś oczekiwał, grób [będzie] moim domem, w ciemności rozłożyłem swoje posłanie. (Sheol )
Bí mo tilẹ̀ ní ìrètí, ipò òku ní ilé mi; mo ti tẹ́ ibùsùn mi sínú òkùnkùn. (Sheol )
14 Powiedziałem do zniszczenia: Jesteś moim ojcem, a robactwu: Moja matko i moja siostro.
Èmi ti wí fún ìdíbàjẹ́ pé, ìwọ ni baba mi, àti fún kòkòrò pé, ìwọ ni ìyá mi àti arábìnrin mi,
15 Gdzie jest więc teraz moja nadzieja? Kto zobaczy moją nadzieję?
ìrètí mi ha dà nísinsin yìí? Bí ó ṣe ti ìrètí mi ni, ta ni yóò rí i?
16 Zstąpią do zasuw grobu, gdy razem odpoczniemy w prochu. (Sheol )
Yóò sọ̀kalẹ̀ lọ sínú ipò òkú, nígbà tí a jùmọ̀ sinmi pọ̀ nínú erùpẹ̀ ilẹ̀?” (Sheol )