< Thimo 20 >

1 Ndibei nĩ mũnyũrũrania, na njoohi nĩ mũndũ wa ngũĩ; mũndũ ũrĩa ũhĩtithagio nĩcio ti mũũgĩ.
Ẹlẹ́yà ni ọtí wáìnì, aláriwo sì ní ọtí líle; ẹnikẹ́ni tí ó bá fi tànjẹ kò gbọ́n.
2 Mangʼũrĩ ma mũthamaki nĩ ta mũraramo wa mũrũũthi; ũrĩa ũmũrakaragia nĩ muoyo wake ateaga.
Ìbẹ̀rù ọba dàbí kíké e kìnnìún; ẹnikẹ́ni tí ó bá mú un bínú ba ayé ara rẹ̀ jẹ́.
3 Gwĩtheema ngũĩ kũrehagĩra mũndũ gĩtĩĩo, no mũndũ o wothe mũkĩĩgu ahiũhaga kũũgitana.
Iyì ni ó jẹ́ fún ènìyàn láti sá fún ìjà, ṣùgbọ́n gbogbo aláìgbọ́n a máa tètè wá ìjà.
4 Kĩgũũta gĩticimbaga hĩndĩ ya irĩma; nĩ ũndũ ũcio hĩndĩ ya magetha gĩathiĩ kũmaatha gĩtirĩ kĩndũ kĩonaga.
Ọ̀lẹ kì í ṣiṣẹ́ oko nígbà tí ó yẹ, nítorí náà ní àsìkò ìkórè, yóò wá kò sì ní rì nǹkan.
5 Muoroto wa ngoro ya mũndũ nĩ ta maaĩ ma ndia ndiku, no mũndũ ũrĩ na ũtaũku nĩamatahaga.
Ète ọkàn ènìyàn dàbí omi jíjìn; ṣùgbọ́n ènìyàn olóye á wá wọn jáde.
6 Andũ aingĩ metuaga marĩ na wendo ũtangĩthira, no mũndũ mwĩhokeku-rĩ, nũũ ũngĩmuona?
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn ni wọ́n máa ń sọ pe àwọn ní ìfẹ́ àìṣẹ̀tàn, ṣùgbọ́n kò rọrùn láti rí ènìyàn olóòtítọ́.
7 Mũndũ mũthingu atũũraga mũtũũrĩre ũtarĩ ũcuuke; kũrathimwo-rĩ, nĩ ciana ciake iria atigaga.
Olódodo ènìyàn a máa gbé ìgbé ayé àìlábùkù ìbùkún ni fún àwọn ọmọ rẹ̀ lẹ́yìn rẹ̀.
8 Rĩrĩa mũthamaki aikarĩra gĩtĩ gĩake kĩa ũnene atue ciira, maitho make mathũngũrũraga ũũru wothe.
Nígbà tí ọba bá jókòó sórí ìtẹ́ rẹ̀ láti ṣe ìdájọ́ yóò fẹ́ gbogbo ibi dànù pẹ̀lú ojú rẹ̀.
9 Nũũ ũngiuga atĩrĩ, “Nĩnjigĩte ngoro yakwa ĩrĩ theru; ndĩ mũtheru, na ndirĩ na mehia”?
Ta ni ó le è wí pé, “Mo ti ṣe ọkàn mi ní mímọ́, mo mọ́, n kò sì lẹ́ṣẹ̀”?
10 Mahiga ma ratiri mataiganainie ũritũ, o na ithimi itaiganĩte: cierĩ nĩ indo irĩ magigi harĩ Jehova.
Ìwọ̀n èké àti òsùwọ̀n ìrẹ́jẹ Olúwa kórìíra méjèèjì.
11 O na kaana kamenyekaga nĩ ũndũ wa ciĩko ciako, gakamenyeka kana mĩtugo yako nĩ mĩtheru, na kana nĩ mĩagĩrĩru.
Kódà a mọ ọmọdé nípa iṣẹ́ rẹ̀ nípa pe bóyá iṣẹ́ rẹ mọ́ tàbí pé ó tọ̀nà.
12 Matũ marĩa maiguaga na maitho marĩa monaga-rĩ, cierĩ nĩ Jehova waciũmbire.
Etí tí ó ń gbọ́ àti ojú tí ó ń ríran Olúwa ni ó dá méjèèjì.
13 Tiga kwenda toro, ndũkae gũthĩĩna; ikaraga wĩiguĩte, na nĩũrĩrĩĩaga irio ũkahũũna.
Má ṣe fẹ́ràn oorun, àìṣe bẹ́ẹ̀ ìwọ yóò di tálákà. Ma ṣe sùn ìwọ yóò sì ní oúnjẹ láti tún fi tọrọ.
14 Mũgũri akĩgũra oigaga atĩrĩ, “Kĩndũ gĩkĩ ti kĩega, ti kĩega!” Agacooka agathiĩ akĩĩrahaga ũrĩa oĩ kũgũra.
“Kò dára, kò dára!” ní ẹni tó ra ọjà máa ń wí; nígbà tí ó bá kúrò níbẹ̀ tán, yóò máa yangàn bí òun tí ṣe rí rà sí.
15 Thahabu nĩ kũrĩ, o na ruru no nyingĩ, no mĩromo ĩrĩa yaragia ũmenyo nĩ ithaga rĩa goro rĩrĩa rĩtonekaga.
Wúrà wà, iyùn sì wà rẹpẹtẹ, ṣùgbọ́n, ahọ́n tí ń sọ ìmọ̀ gan an ni ọ̀ṣọ́ iyebíye.
16 Oya nguo ya mũndũ ũrĩa ũngĩrũgamĩrĩra thiirĩ wa mũndũ wa kũngĩ; mĩige ĩrũgamĩrĩre thiirĩ ũcio wa mũndũ wa kũngĩ.
Gba abọ́ ẹni tí ó ṣe onídùúró fún àlejò; mú un lọ́wọ́ bí ìbúra bí ó bá ṣe é fún obìnrin onírìnkurìn.
17 Irio cionekete na njĩra ya kũheenania irĩ cama harĩ mũndũ, no thuutha kanua gake kaiyũraga o mũthanga.
Oúnjẹ tí a fi ọ̀nà èrú rí máa ń dùn lẹ́nu ènìyàn, ṣùgbọ́n, a yọrí sí ibi ẹnu tí ó kún fún erùpẹ̀.
18 Mĩbango ĩgaacagĩra nĩ ũndũ wa kũhooya kĩrĩra, ũngĩtua gũthiĩ mbaara-inĩ, heo ũtaaro.
Pa ètè rẹ mọ́ nípa wíwá ìmọ̀ràn bí o bá ń jagun, gba ìtọ́sọ́nà.
19 Mũndũ wa mũhuhu nĩoimagia ndeto cia ndundu nja, nĩ ũndũ ũcio wĩthemage mũndũ waragia mũno.
Olófòófó a máa tú àṣírí nítorí náà yẹra fún ènìyàn tí ń rojọ́ púpọ̀.
20 Mũndũ angĩruma ithe kana nyina, tawa wake ũkaahorera nduma-inĩ ĩrĩa ndumanu.
Bí ènìyàn kan bá ṣépè fún baba tàbí ìyá rẹ̀, ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ ni a ó pa kú nínú òkùnkùn biribiri.
21 Igai rĩrĩa rĩoneka narua kĩambĩrĩria-inĩ, marigĩrĩrio-inĩ rĩtituĩkaga rĩa kĩrathimo.
Ogún tí a kójọ kíákíá ní ìbẹ̀rẹ̀ kì yóò ní ìbùkún ní ìgbẹ̀yìn gbẹ́yín.
22 Ndũkoige atĩrĩ, “Nĩngerĩhĩria ũũru ũyũ!” Eterera Jehova nake nĩegũkũhonokia.
Má ṣe wí pé, “N ó sẹ̀san àṣìṣe rẹ yìí fún ọ.” Dúró de Olúwa yóò sì gbà ọ́ là.
23 Mahiga ma ratiri mataiganainie ũritũ nĩ kĩndũ kĩrĩ magigi harĩ Jehova, nacio ratiri itarĩ cia ma itimũkenagia.
Olúwa kórìíra òdínwọ̀n èké. Òsùwọ̀n ìrẹ́jẹ kò sì tẹ́ ẹ lọ́rùn.
24 Makinya ma mũndũ matongoragio nĩ Jehova. Mũndũ-rĩ, angĩkĩhota atĩa kũmenya njĩra yake mwene?
Olúwa ni ó ń ṣe olùdarí ìgbésẹ̀ ènìyàn. Báwo wá ni òye gbogbo ọ̀nà ènìyàn ṣe le yé ni?
25 Nĩ mũtego harĩ mũndũ kwamũrĩra Ngai kĩndũ na ihenya, acooke gwĩcũũrania ũhoro wa mĩĩhĩtwa yake thuutha-inĩ.
Ìdẹ̀kùn ni fún ènìyàn láti ṣe ìlérí kíákíá nígbà tí ó bá sì yá kí ó máa ro ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ wò.
26 Mũthamaki mũũgĩ nĩathũngũrũraga andũ arĩa aaganu; ageragĩria kĩgaragari gĩa gũkonyora ngano igũrũ rĩao.
Ọlọ́gbọ́n ọba tú ènìyàn búburú ká; Ó sì fi òòlọ ìpakà lọ̀ wọ́n.
27 Roho wa mũndũ nĩ tawa wa Jehova, ũthuthuuragia o nginya tũturi tũrĩa tũrĩ thĩinĩ mũno.
Àtùpà Olúwa ń ṣe àwárí ẹ̀mí ènìyàn a máa ṣàwárí ibi ìkọ̀kọ̀ inú.
28 Wendo na wĩhokeku nĩcigitagĩra mũthamaki; ũtugi nĩũtũmaga gĩtĩ gĩake kĩa ũnene kĩrũme.
Ìfẹ́ àti òdodo pa ọba mọ́, nípa ìfẹ́, ìtẹ́ rẹ̀ wà láìléwu.
29 Hinya wa andũ ethĩ nĩguo riiri wao, nacio mbuĩ nĩcio riiri wa arĩa akũrũ.
Ògo àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin ni agbára wọn, ewú orí ni iyì arúgbó.
30 Mahũũra na nguraro nĩitheragia ũũru wa mũndũ, nacio iboko itheragia o nginya tũturi twa thĩinĩ mũno.
Ìgbájú ìgbámú àti ìfarapa máa ń mú ibi lọ, pàṣán sì máa ń ṣe àfọ̀mọ́ ibi ìkọ̀kọ̀ inú.

< Thimo 20 >