< Isaia 31 >

1 Kaĩ arĩa maikũrũkaga magathiĩ bũrũri wa Misiri gwetha ũteithio marĩ na haaro-ĩ, o acio mehokaga hinya wa mbarathi, na makehoka ũingĩ wa ngaari cia ita, na makehoka hinya mũnene wa andũ arĩa mathiiaga mahaicĩte mbarathi, na makaaga gũcũthĩrĩria Ũrĩa Mũtheru wa Isiraeli, o na makaaga gũcaria ũteithio kuuma kũrĩ Jehova.
Ègbé ni fún àwọn tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ sí Ejibiti fún ìrànlọ́wọ́, tí wọn gbẹ́kẹ̀lé ẹṣin tí wọ́n fi ìgbẹ́kẹ̀lé wọn sí ọ̀pọ̀lọpọ̀ kẹ̀kẹ́-ẹṣin wọn àti agbára ńlá àwọn ẹlẹ́ṣin wọn, ṣùgbọ́n tiwọn kò bojú wo Ẹni Mímọ́ Israẹli n nì, tàbí kí wọn wá ìrànlọ́wọ́ lọ́dọ̀ Olúwa.
2 No rĩrĩ, o nake Jehova nĩ mũũgĩ na no amarehithĩrie mwanangĩko, nĩgũkorwo ndericũkagwo ũrĩa oigĩte. We nĩakarahũka okĩrĩre nyũmba ya andũ arĩa aaganu, na okĩrĩre arĩa mateithagĩrĩria andũ arĩa mekaga maũndũ mooru.
Síbẹ̀síbẹ̀ òun pẹ̀lú jẹ́ ọlọ́gbọ́n ó sì lè mú ìparun wá; òun kì í kó ọ̀rọ̀ rẹ̀ jẹ. Òun yóò dìde sí ilé àwọn ìkà, àti sí àwọn tí ń ṣe ìrànlọ́wọ́ fún aṣebi.
3 No rĩrĩ, andũ a Misiri no andũ tu, na ti Mũrungu; nacio mbarathi ciao no nyama na itirĩ roho thĩinĩ wacio. Rĩrĩa Jehova aatambũrũkia guoko gwake, ũcio ũteithanagia nĩahĩngagwo, na ũcio ũteithagio nĩagũũaga; nao eerĩ makaaniinwo hamwe.
Ṣùgbọ́n ènìyàn lásán ni àwọn ará Ejibiti wọn kì í ṣe Ọlọ́run; ẹran-ara ni àwọn ẹṣin wọn, kì í ṣe ẹ̀mí. Nígbà tí Olúwa bá na ọwọ́ rẹ̀ jáde, ẹni náà tí ó ń ṣèrànwọ́ yóò kọsẹ̀, ẹni náà tí à ń ràn lọ́wọ́ yóò ṣubú; àwọn méjèèjì yóò sì jùmọ̀ parun.
4 Jehova anjĩĩrĩte atĩrĩ: “O ta ũrĩa mũrũũthi ũraramaga, mũrũũthi njamba ũkĩrĩa nyamũ ĩrĩa ũnyiitĩte, na ndũmakagio nĩ mĩgambo ya arĩithi o na mokĩte marĩ gĩkundi kĩnene metĩtwo hamwe nĩguo maũũkĩrĩre, kana wĩtigĩre nĩ ũndũ wa inegene rĩao-rĩ, ũguo noguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe agaikũrũka, arũe arĩ kũu Kĩrĩma-inĩ gĩa Zayuni, o na ciambatĩro ciakĩo.
Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Gẹ́gẹ́ bí i kìnnìún ti í ké àní kìnnìún ńlá lórí ẹran ọdẹ rẹ̀ bí a tilẹ̀ rí ẹgbẹ́ àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí a sì pè wọ́n papọ̀ láti kojú rẹ̀, ẹ̀rù kò lè bà á pẹ̀lú igbe wọn akitiyan wọn kò sì lè dí i lọ́wọ́ bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò sọ̀kalẹ̀ wá láti jagun lórí òkè Sioni àti lórí ibi gíga rẹ̀.
5 O ta ũrĩa nyoni ĩreeraga rĩera-inĩ, ũguo noguo Jehova Mwene-Hinya-Wothe akaagitĩra itũũra rĩa Jerusalemu; akaarĩgitĩra na arĩkũũre, ‘akaahĩtũkĩra igũrũ rĩa rĩo’ nĩguo arĩhonokie.”
Gẹ́gẹ́ bí àwọn ẹyẹ ti ń rábàbà lókè Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò dáàbò bo Jerusalẹmu, Òun yóò dáàbò bò ó, yóò sì tú u sílẹ̀ Òun yóò ré e kọjá yóò sì gbà á sílẹ̀.”
6 Inyuĩ andũ a Isiraeli-rĩ, cookererai ũcio mũtũire mũremeire mũno.
Ẹ padà sọ́dọ̀ ẹni tí ẹ ti ṣọ̀tẹ̀ sí gidigidi, ẹ̀yin ọmọ Israẹli.
7 Nĩgũkorwo mũthenya ũcio o mũndũ wanyu nĩagatee mĩhianano ya betha na ya thahabu ĩrĩa mwĩthondekeire na moko manyu ĩgatũma mwĩhie.
Nítorí ní ọjọ́ náà, ẹnìkọ̀ọ̀kan yín yóò kọ àwọn ère fàdákà àti wúrà tí ọwọ́ ẹ̀ṣẹ̀ yín ti ṣe.
8 “Andũ a Ashuri makooragwo na rũhiũ rwa njora no ti rwa mũndũ; rũhiũ rwa njora nĩruo rũkaamaniina biũ, no ti rwa andũ. Nĩmakoorĩra rũhiũ rũu rwa njora, na aanake ao makaanyiitwo, marutithio wĩra na hinya.
“Asiria yóò ṣubú lọ́wọ́ idà kan tí kò ti ọwọ́ ènìyàn wá; idà tí kì í ṣe ti ẹ̀dá alààyè ni yóò pa wọ́n. Wọn yóò sì sá níwájú idà náà àti àwọn ọmọkùnrin wọn ni a ó fún ní iṣẹ́ ipá ṣe.
9 Nacio ciĩhitho ciao cia hinya nĩikaagũa nĩ ũndũ wa guoya; nao anene ao a ita moona bendera ya ita nĩmakamaka mũno,” ũguo nĩguo Jehova ekuuga, ũrĩa wakĩtie mwaki wake Zayuni, o na icua rĩake rĩa mwaki rĩrĩ kũu Jerusalemu.
Àpáta rẹ yóò kọjá lọ fún ẹ̀rù; àwọn olórí rẹ yóò bẹ̀rù asia náà,” ni Olúwa wí, ẹni tí iná rẹ̀ ń bẹ ní Sioni, ẹni tí ìléru rẹ̀ wà ní Jerusalẹmu.

< Isaia 31 >