< Amos 8 >
1 Khenah, Angraeng Sithaw mah nipui tue ih thingthai kahmin benthang maeto ang hnuksak.
Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè fihàn mi: agbọ̀n èso pípọ́n.
2 Anih mah, Amos, timaw na hnuk, tiah ang naa. Kai mah, nipui tue ih thingthai kahmin benthang maeto ka hnuk, tiah ka naa. To pacoengah Angraeng mah kai khaeah, Kai ih kami Israelnawk boenghaih tue to phak boeh; nihcae tahmen lethaih ka tawn mak ai boeh, tiah ang thuih.
Ó béèrè pé, “Amosi kí ni ìwọ rí.” Mo sì dáhùn pé, “Agbọ̀n èso pípọ́n.” Nígbà náà ni Olúwa wí fún mi pé, “Àsìkò náà pọ́n tó fún àwọn ènìyàn mi Israẹli; Èmi kì yóò dá wọn sí mọ́.”
3 Angraeng Sithaw mah, To na niah loe tempul thung ih laa lok to qahhaih lok ah angcoeng tih: ahmuen kruekah kadueh qok to om ueloe, angqai krang ah va o sut tih, tiah ang naa.
Olúwa Olódùmarè wí pé, “Ní ọjọ́ náà, àwọn orin tẹmpili yóò yí padà sí ohùn réré ẹkún. Ọ̀pọ̀, àní ọ̀pọ̀ ara òkú ni yóò wà ni ibi gbogbo! Àní ni ìdákẹ́ jẹ́ẹ́!”
4 Prae thung ih mithoe kaminawk to paaeh moe, amtang kaminawk amtimsak kaminawk hae lok hae tahngai oh.
Ẹ gbọ́ èyí, ẹ̀yin tí ń tẹ aláìní lórí ba, tí ẹ sì ń sọ tálákà di ilẹ̀.
5 Natuek naah maw khrah kangtha boeng tih? Kamtong to zawh hanah ka koeh o boeh; natuek naah maw Sabbath boeng tih? Cang zawh han ka koeh o boeh, tiah na thuih o; ephah kazit to anghoep toep ah na sak o, shekel kalen to kathoeng kae ah na sak o pacoengah, katoeng ai coih tahhaih to na patoh o:
Tí ẹ ń wí pé, “Nígbà wo ni oṣù tuntun yóò parí kí àwa bá à lè ta ọkà kí ọjọ́ ìsinmi kí ó lè dópin kí àwa bá à le ta jéró?” Kí a sì dín ìwọ̀n wa kù kí a gbéraga lórí iye tí a ó tà á kí a sì fi òsùwọ̀n èké yàn wọ́n jẹ,
6 amtang kaminawk to sum kanglung hoiah na qan o moe, mithoe kaminawk to khokpanai maeto hoiah na qan o, kahoih ai cangnawk doeh na zawh o.
kí àwa lè fi fàdákà ra àwọn tálákà, kí a sì fi bàtà ẹsẹ̀ méjèèjì ra aláìní, kí a sì ta jéró tí a kó mọ́ ilẹ̀.
7 Jakob amoek haih pongah nihcae toksakhaihnawk to natuek naah doeh ka pahnet mak ai, tiah Angraeng mah lokkamhaih to sak.
Olúwa ti fi ìgbéraga Jakọbu búra pé, “Èmi kì yóò gbàgbé ọ̀kan nínú ohun tí wọ́n ṣe.
8 Hae pongah prae anghuenh ueloe, a thungah kaom kaminawk to palungsae o boih mak ai maw? Prae boih tuipui baktiah angthawk tih, Izip prae ih tuipui baktiah, tui mah pazawk ueloe, uem boih tih.
“Ǹjẹ́ ilẹ̀ náà kì yóò ha wárìrì fún èyí? Àwọn tí ń gbé inú rẹ̀ kì yóò ha ṣọ̀fọ̀? Gbogbo ilẹ̀ yóò ru sókè bí omi Naili, yóò sì ru ú sókè pátápátá bí ìkún omi a ó sì tì í jáde, a ó sì tẹ̀ ẹ́ rì gẹ́gẹ́ bí odò Ejibiti.
9 To na niah loe, Athun ah ni ka duemsak moe, khodai ah long to kho ka vingsak han:
“Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa Olódùmarè wí, “Èmi yóò mú oòrùn wọ̀ ní ọ̀sán, Èmi yóò mú kí ayé ṣókùnkùn ní ọ̀sán gangan.
10 na sak o ih poihnawk to palungsethaih ah kang coengsak moe, na sak o ih laanawk doeh qahhaih ah kang coengsak boih han; kaeng ah buri kahni kang zaeng o sak boih moe, lu sam kang aah o sak boih han; to atue loe capa maeto khue katawn kami palungsethaih baktiah kang oh o sak han, boenghaih loe kakhaa ni baktiah om tih, tiah Angraeng Sithaw mah thuih.
Èmí yóò yí àsè ẹ̀sìn yín padà sí ọ̀fọ̀, gbogbo orin yín ni èmi yóò sọ di ẹkún. Èmi yóò mú kí gbogbo yín wọ aṣọ ọ̀fọ̀, kí a sì fá orí yín. Èmi yóò mú kí ìgbà náà rí bí ìṣọ̀fọ̀ fún ọmọkùnrin kan ṣoṣo tí a bí àti òpin rẹ̀ bí ọjọ́ kíkorò.
11 Angraeng Sithaw mah, Khenah, ani loe angzoh boeh, prae thungah takang thohhaih ka patoeh han, buh takang thohhaih ih na ai, tui takang thohhaih doeh na ai ah, Angraeng lok takang thohhaih to ka phaksak han.
“Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa Olódùmarè wí, “nígbà tí èmi yóò rán ìyàn sí ilẹ̀ náà, kì í ṣe ìyàn oúnjẹ tàbí òǹgbẹ fún omi. Ṣùgbọ́n ìyàn gbígbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa.
12 Kaminawk mah tuipui maeto hoi maeto bangah caeh o ueloe, aluek bang hoi ni angyae bang khoek to avak o tih; nihcae mah Angraeng ih lok pakrong hanah, ahnuk ahmaa cawn o tih; toe hnu o mak ai.
Àwọn ènìyàn yóò rìn kiri láti Òkun dé Òkun wọn yóò sì máa rìn ká láti gúúsù sí àríwá, wọn yóò máa wá ọ̀rọ̀ Olúwa ṣùgbọ́n wọn kì yóò rí i.
13 To na niah kranghoih kacuem tanglanawk hoi thacak thendoengnawk loe tui anghaeh loiah thazok o sut tih.
“Ní ọjọ́ náà “àwọn arẹwà wúńdíá àti àwọn alágbára ọ̀dọ́mọkùnrin yóò dákú fún òǹgbẹ omi.
14 Samaria mah sak ih zaehaih hoiah lokkamhaih sah kaminawk hoi Aw Dan, na sithaw loe hing! Beersheba ih loklam loe hing! tiah thui kaminawk loe amtim o tih, natuek naah doeh angthawk o let mak ai boeh.
Àwọn tí ó fi ẹ̀ṣẹ̀ Samaria búra, tí wọ́n sì wí pé, ‘Bí ó ti dájú pé ọlọ́run rẹ ń bẹ láààyè, ìwọ Dani,’ bí ó ti dájú pè ọlọ́run rẹ ń bẹ láààyè, ìwọ Beerṣeba, wọ́n yóò ṣubú, wọn kì yóò si tún dìde mọ.”