< 2 Hou Olelesu 35 >

1 Hina bagade Yousaia da Hina Godema nodone, Yelusalemega Baligisu Lolo Nasu hamoi. Eso ba: , oubi agega, ilia da Lolo Nasu hamoma: ne, ohe medole lelegei.
Síwájú sí i, Josiah ṣe ìrántí àjọ ìrékọjá sí Olúwa ní Jerusalẹmu, Ọ̀dọ́-àgùntàn àjọ ìrékọjá náà ni wọ́n sì pa ní ọjọ́ kẹrìnlá oṣù kìn-ín-ní.
2 E da gobele salasu dunu, ilia Debolo Diasu ganodini hawa: hamosu amo ilima ilegei. Amola amo noga: le hawa: hamoma: ne, e da ilia dogo denesima: ne sia: i.
Ó sì yàn àwọn àlùfáà sí iṣẹ́ wọn, ó sì gbà wọ́n ní ìyànjú ní ìsìn ilé Olúwa.
3 Amola e da Lifai fi dunu (ilia da Isala: ili fi ilima olelesu dunu, Hina Gode Ea momogili gagai galu) ilima amane hamoma: ne sia: i, “Dilia Gode Ea Hadigi Gousa: su Sema Gagili amo Debolo Diasu (hina bagade Soloumane, Da: ibidi egefe ea gagui) amo ganodini ligisima. Dilia amo soge eno, soge enoga gaguli ahoasu hou fisili, guiguda: dilia Hina Gode amola Ea fi Isala: ili dunu ilima hawa: hamoma.
Ó sì wí fún àwọn ọmọ Lefi, ẹni tí ń kọ́ gbogbo àwọn Israẹli ẹni tí a ti yà sí mímọ́ fún Olúwa pé ẹ gbé àpótí ẹ̀rí ìyàsọ́tọ̀ sí ilé Olúwa tí Solomoni ọmọ Dafidi ọba Israẹli ti kọ́. Kò gbọdọ̀ jẹ́ ẹrù àgbéká ní èjìká rẹ̀. Nísinsin yìí ẹ sin Olúwa Ọlọ́run yín àti àwọn ènìyàn rẹ̀ Israẹli.
4 Dilia sosogo fi defele, amola dilia hawa: hamosu amo hina bagade Da: ibidi amola egefe hina bagade Soloumane ela dilima ilegei, amo defele, Debolo Diasu ganodini hawa: hamoma.
Ẹ múra sílẹ̀ nípa ìdílé ní ẹsẹẹsẹ yín gẹ́gẹ́ bí àpẹẹrẹ tí a kọ́ láti ọwọ́ Dafidi ọba Israẹli àti gẹ́gẹ́ bí ọmọ rẹ̀ Solomoni.
5 Dilia Isala: ili sosogo fi afae afae noga: le fidima: ne momagema.
“Dúró ní ibi mímọ́ pẹ̀lú àkójọpọ̀ àwọn ọmọ Lefi fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ìpín àwọn ìdílé àwọn ẹgbẹ́ ará ìlú, àwọn ènìyàn tí ó dùbúlẹ̀.
6 Dilia Baligisu Lolo Nasu sibi mano amola goudi huluane medole legema: ne momagema. Amaiba: le, Isala: ili fi dunu da hamoma: ne sia: i amo Hina Gode da Mousese ea lafidili, ninima i, amo noga: le fa: no bobogema: ne, dilia nigima: dodofema, amola gobele salimusa: ohe momagema.”
Ẹ pa ẹran àjọ ìrékọjá náà, ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ kí ẹ sì pèsè ẹran fún àwọn ẹgbẹ́ arákùnrin yín, kí ẹ sì ṣe ohun tí Olúwa paláṣẹ láti ọwọ́ Mose.”
7 Yuda fi dunu da Baligisu gobele salasu hamoma: ne, hina bagade Yousaia da hina: ohe fofoi wa: i amoga sibi, sibi mano amola goudi mano gilisi 30,000 agoane, amola bulamagau gawali 3,000 agoane i.
Josiah sì pàṣẹ fún gbogbo àwọn ènìyàn tí ó dùbúlẹ̀ tí ó wà níbẹ̀ iye rẹ̀ jẹ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dógún ọ̀dọ́-àgùntàn àti ọmọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ìrékọjá, àti pẹ̀lú ẹgbẹ̀rún mẹ́ta akọ màlúù, gbogbo wọ̀nyí jẹ́ ohun ìní láti ọ̀dọ̀ ọba.
8 Yousaia eagene ouligisu dunu da gobele salasu ohe mogili, dunudafa, gobele salasu dunu amola Lifai fi dunu ilima i. Amola Debolo Diasu ouligisu dunu amo gobele salasu dunuma sibi mano 2,600 agoane, goudi mano mogili amola bulamagau gawali 300 agoane amo gobele salima: ne ilima i.
Àwọn ìjòyè rẹ̀ fi tinútinú ta àwọn ènìyàn náà ní ọrẹ àti àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi. Hilkiah, Sekariah àti Jehieli, àti àwọn olórí ilé Ọlọ́run, fún àwọn àlùfáà ní ẹgbẹ̀tàlá ẹbọ àjọ ìrékọjá àti ọ̀ọ́dúnrún ẹran ọ̀sìn.
9 Lifai fi ouligisu dunu amo Gononia, Siema: ia, Nida: niele (Siema: ia eya), Ha: siabaia, Yiaiele amola Yosaba: de - ilia da sibi mano amola goudi waha debe mogili 5000 agoane, amola bulamagau gawali 500 agoane - amo Lifai dunu ilia gobele salimusa: ilima i.
Àti pẹ̀lú Konaniah àti pẹ̀lú Ṣemaiah àti Netaneli, àti àwọn arákùnrin rẹ̀, àti Haṣabiah, Jeieli àti Josabadi olórí àwọn ọmọ Lefi, ó sì pèsè ẹgbẹ̀rún márùn-ún ẹbọ ìrékọjá àti ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta orí ẹran ọ̀sìn fún àwọn ọmọ Lefi.
10 Baligisu Lolo Nasu liligi huluane da momagei dagoloba, hina bagade da amo hamoma: ne sia: beba: le, gobele salasu amola Lifai fi dunu da ilila: sogebiga dadalei.
Nítorí náà, a múra ìsìn náà sílẹ̀, àwọn àlùfáà sì dúró ní ipò wọn pẹ̀lú àwọn ọmọ Lefi nípa iṣẹ́ wọn gẹ́gẹ́ bí ọba ti pa á láṣẹ.
11 Ilia da sibi mano amola goudi medole lelegelalu, Lifai fi dunu da ilia gadofo houga: i. Gobele salasu dunu da maga: me oloda da: iya fogagaga: la: i.
Ní ti àjọ ìrékọjá a sì pa ẹran, àwọn àlùfáà sì wọ́n ẹ̀jẹ̀ náà tí wọ́n gbé sí ọwọ́ wọn, nígbà tí àwọn ọmọ Lefi sì bọ ẹranko.
12 Amalalu, ilia da Mousese ea Sema dedei defele, Hina Godema gobele salimusa: , ilia da sosogo fi afae afae ilima amo ohe gogo fane i.
Wọ́n sì ya àwọn ẹbọ sísun sí apá kan láti fi wọ́n fún gẹ́gẹ́ bí ìpín àwọn ìdílé àwọn ènìyàn láti rú ẹbọ sí Olúwa. Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sínú ìwé Mose. Wọ́n sì ṣe bákan náà pẹ̀lú àwọn ẹran ọ̀sìn.
13 Lifai fi dunu da God Ea hamoma: ne sia: i dedei defele, Baligisu gobele salasu ohe liligi amo laluma gobele gala: i. Amola ilia da hadigi iasu liligi amo gobele nasu ofodo, sosobeni amola gaga ganodini gobei. Amalalu, ilia hedolowane hu gobei amola dunu ilima sagoi.
Wọ́n sì fi sun àjọ ìrékọjá lórí iná gẹ́gẹ́ bí ìlànà, wọ́n sì bọ ẹbọ mímọ́ nínú ìkòkò, nínú ọpọ́n àti nínú agbada, wọ́n sì pín wọn kíákíá fún gbogbo àwọn ènìyàn.
14 Amalu, Lifai fi dunu da ili manusa: , amola Elane egaga fi gobele salasu dunu ili moma: ne, hu momagele legei. Bai gobele salasu dunu da hawa: hamonanawane gasi. Ilia da ohe mogili gogo gobele sali, amola eno ohe amoga sefe duga: i, amo gobele sali.
Lẹ́yìn èyí, wọ́n sì múra sílẹ̀ fún ara wọn àti fún àwọn àlùfáà nítorí àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Aaroni, ni wọ́n rú ẹbọ sísun àti ọ̀rá títí di àṣálẹ́. Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Lefi sì múra sílẹ̀ fún ara wọn àti fún àwọn ọmọ Aaroni àlùfáà.
15 Da: ibidi ea musa: hamoma: ne sia: i defele, Lifai fi amola A: isa: fe sosogo gesami hea: lala dusu dunu, ilia da ilila: hawa: hamosua lefulubi ba: i. Ilia dio da A: isa: fe, Hima: ne amola Yediudane (hina bagade ea balofede dunu). Debolo Diasu logo ga: su sosodo aligisu dunu da ilia sosodo aligisu sogebi fisili hame ahoasu. Bai Lifai fi dunu oda da Baligisu Lolo ilia moma: ne momagei.
Àwọn akọrin, àwọn ọmọ Asafu, ni wọ́n wà ní ipò wọn tí a sì paláṣẹ fún wọn láti ọwọ́ Dafidi, Asafu, Hemani àti Jedutuni àwọn aríran ọba àti àwọn olùṣọ́nà ní olúkúlùkù ẹnu-ọ̀nà kò gbọdọ̀ fi ojú ọ̀nà wọn sílẹ̀, nítorí àwọn ẹgbẹ́ ọmọ lefi ti múra sílẹ̀ fún wọn.
16 Amaiba: le, hina bagade Yousaia ea hamoma: ne sia: i defele, ilia da Baligisu Lolo Nasu amola oloda da: iya gobele salasu hou, amo huluane ilia da Hina Godema nodomusa: hamoi.
Bẹ́ẹ̀ ni àsìkò náà gbogbo àwọn ìsìn Olúwa ni wọ́n gbé jáde fún iṣẹ́ ìrántí àjọ ìrékọjá àti láti rú ẹbọ sísun lórí pẹpẹ Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ọba Josiah ti pa á láṣẹ.
17 Eso fesuale amoga, Isala: ili fi dunu huluane Yelusalemega esalu, ilia da Baligisu Lolo Nasu amola Agi Yisidi Hame Sali Lolo Nasu hahawane hamoi.
Àwọn ọmọ Israẹli tí ó gbé kalẹ̀ ṣe ìrántí àjọ ìrékọjá ní àkókò náà àti àjọ àkàrà àìwú fún ọjọ́ méje.
Àjọ ìrékọjá náà kò sì tí ì sí èyí tí ó dàbí i rẹ̀ ní Israẹli títí dé ọjọ́ wòlíì Samuẹli, kò sì sí ọ̀kan lára àwọn ọba Israẹli tí ó pa irú àjọ ìrékọjá bẹ́ẹ̀ mọ́ gẹ́gẹ́ bí Josiah ti ṣe, pẹ̀lú àwọn àlùfáà àwọn ọmọ Lefi àti gbogbo àwọn Juda àti Israẹli tí ó wà níbẹ̀ pẹ̀lú gbogbo ènìyàn Jerusalẹmu.
19 Balofede dunu Sa: miuele ea fifi misi eso amogalu, ilia agoane hamedafa hamosu. Isala: ili hina bagade musa: fifi masu, ilia da Baligisu Lolo Nasu amo hina bagade Yousaia, gobele salasu dunu, Lifai fi dunu amola Isala: ili amola Yuda amola Yelusaleme fi dunu ilia da Yousaia ea ouligisu ode 16 amoga hamoi, agoai afae hamedafa hamoi.
Àjọ ìrékọjá yìí ni a ṣe ìrántí ní ọdún kejìdínlógún ìjọba Josiah.
20 Hina bagade Yousaia da Debolo Diasu hou noga: le hahamoi. Amogalu, Idibidi hina bagade Nigou da ea dadi gagui wa: i oule, Gagimisi moilai bai bagade (Iufala: idisi Hano bega: dialu) amo doagala: musa: wa: i misi. Yousaia da e gagabomusa: dawa: i.
Lẹ́yìn gbogbo èyí nígbà tí Josiah ti tún ilẹ̀ náà ṣetán, Neko ọba Ejibiti gòkè lọ láti bá Karkemiṣi jà lórí odo Eufurate, Josiah sì jáde lọ láti pàdé rẹ̀ ní ibi ìjà.
21 Be Nigou da Yousaiama amo sia: adoma: ne sia: si, “Yuda hina bagade! Amo gegesu na waha gegenanebe da dia liligi hame. Na da dima hame gegena misi. Be na da na ha lai dunuma gegena misi. Amola Gode da hedoloma: ne nama adoi. Gode da nama gaiba: le, E da di gugunufinisisa: besa: le, na logo mae hedofama!”
Ṣùgbọ́n Neko rán ìránṣẹ́ sí i wí pé, “Ìjà wo ni ó ń bẹ láàrín èmi àti ìwọ, ọba Juda? Kì í ṣe ìwọ ni èmi tọ̀ wá ní àkókò yìí, ṣùgbọ́n, ilé pẹ̀lú èyí ti mo bá níjà. Ọlọ́run ti sọ fún mi láti yára àti láti dúró nípa ṣíṣe ìdènà Ọlọ́run, ẹni tí ó wà pẹ̀lú mi, kí òun má bá a pa ọ́ run.”
22 Be Yousaia da dafawane gegemusa: dawa: i. E da Gode Ea sia: , Nigou ea lafidili sia: be, amo nabimu higa: i galu. Amaiba: le, e da ea da: i afadenene, Migidou umi amoga gegemusa: asi.
Josiah, kò yípadà kúrò lọ́dọ̀ rẹ̀, ṣùgbọ́n ó pa ara rẹ̀ dà kí ó le bá a jà, kó sì fi etí sí ọ̀rọ̀ Neko láti ẹnu Ọlọ́run wá, ó sì wá jagun ní àfonífojì Megido.
23 Gegenana, Idibidi dunu da gala: gonoba, hina bagade Yousaia da ludi dagoi. E da ea hawa: hamosu dunuma amane sia: i, “Na da se bagade nababeba: le, na enodi gaguli masa!”
Tafàtafà sì ta ọfà sí ọba Josiah, ó sì sọ fún àwọn ìjòyè pé, “Ẹ gbé mi kúrò, èmi ti gba ọgbẹ́ gidigidi.”
24 Ilia da e sa: liode da: iya dialu, laleguduli, eno sa: liode da: iya ligisili, Yelusalemega gaguli asi. Amogawi, e da bogobeba: le, ilia da ea da: i hodo amo hina bagade ilia bogoi gele gelaba ligisila asi. Yuda fi dunu amola Yelusaleme fi dunu huluane da e bogoiba: le didigia: i.
Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì gbé e jáde kúrò nínú kẹ̀kẹ́ náà, wọ́n sì gbé e sínú kẹ̀kẹ́ mìíràn, wọ́n sì gbé e wá sí Jerusalẹmu, níbi tí ó ti kú, wọ́n sì sin ín sínú ọ̀kan nínú àwọn ibojì àwọn baba rẹ̀, gbogbo Juda àti gbogbo Jerusalẹmu sì ṣọ̀fọ̀ Josiah.
25 Balofede dunu Yelemaia da Yousaia dawa: musa: , fofagini gesami hahamoi. Wali, Isala: ili gesami hea: su dunu amola uda da Yousaia ea hou dawa: beba: le, didigia: sea, ilia da amo gesami hea: sa. Amo gesami hea: su da fofagini gesami hea: su dedei buga ganodini dedene legei dagoi.
Jeremiah sì pohùnréré ẹkún fún Josiah, gbogbo àwọn akọrin ọkùnrin àti gbogbo àwọn akọrin obìnrin sì ń sọ ti Josiah nínú orin ẹkún wọn ní Israẹli títí di òní. Èyí sì di àṣà ní Jerusalẹmu, a sì kọ ọ́ sínú àwọn orin ẹkún.
26 Yousaia ea hamonanu huluane - ea Hina Godema asigi hou, ea Sema amoma nabasu hou,
Ìyókù iṣẹ́ ìjọba Josiah àti ìwà rere rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí èyí tí a ti kọ sínú ìwé òfin Olúwa.
27 amola ea hawa: hamonanu hemosu asili dagosu - amo huluane da “Isala: ili amola Yuda hina bagade ilia Hamonanu Meloa”, amo ganodini dedene legei.
Gbogbo iṣẹ́ náà, láti ìbẹ̀rẹ̀ títí dé òpin ni a kọ sínú ìwé àwọn ọba Israẹli àti Juda.

< 2 Hou Olelesu 35 >